Publicidade

1 Coríntios 7

Ìgbéyàwó

1 báyìí, nítorí àwọn ohun ṣe kọ̀: Ó dára fún ọkùnrin ó máa ṣe ni ìdàpọ̀ pẹ̀obìnrin. 2 Ṣùgbọ́n nítorí àgbèrè pọ̀ bẹ́̀ gẹ́́ ọkùnrin kọ̀̀kan gbéyàwó tirẹ̀. Bẹ́̀ ni obìnrin kọ̀̀kan ọkọ tirẹ̀. 3 ọkùnrin ó fi gbogbo ̀tọ́ ìyàwó rẹ̀ fún ún, ìyàwó fi gbogbo ̀tọ́ ọkọ fún ọkọ rẹ̀. 4 Aya láṣẹ lórí ara rẹ̀ mọ́, ara rẹ̀ ti di ti ọkọ rẹ̀. Bákan náà ni ọkùnrin ó gbéyàwó àṣẹ lórí ara rẹ̀ mọ́, ara rẹ̀ ti di ti ìyàwó rẹ̀. 5 7.5: Ek 19.15.Nítorí náà, ṣe fi àwọn ̀tọ́ tọkọtaya wọ̀nyí dun ara yín, ṣe nípa ìfìmọ̀ṣọ̀kan, ̀yin fi ara yín fún àwẹ̀ àti àdúrà, ̀yin tún jùmọ̀ pàdé, lẹ́yìn ìgbà náà, wọ́n gbọdọ̀ padà sọ́dọ̀ ara wọn Satani ba à dán wọn nítorí àìlèmáradúró wọn. 6 Mo sọ èyí fún un yín ìmọ̀ràn í ṣe àṣẹ. 7 7.7: 1Kọ 7.8; 9.5.Ó olúkúlùkù dàbí èmi, ṣùgbọ́n gbogbo ènìyàn le jẹ́ bákan náà, Ọlọ́run fún olúkúlùkù ènìyàn ̀bùn tirẹ̀, ̀kan irú èyí àti èkejì irú òmíràn.

8 Nítorí náà, mo fún àwọn àpọ́n àti opó , ó sàn wọ́n kúkú gẹ́gẹ́ èmi . 9 7.9: 1Tm 5.14.Ṣùgbọ́n wọ́n ara dúró, wọ́n gbéyàwó tàbí wọ́n fẹ́ ọkọ, nítorí ó sàn láti gbéyàwó láti ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́ lọ.

10 Àwọn ti ó ti gbéyàwó àti àwọn ó lọ́kọ, ni mo fẹ́ pa á láṣẹ fún í ṣe láti ̀dọ̀ mi ṣùgbọ́n láti ̀dọ̀ Olúwa: "Obìnrin gbọdọ̀ kọ́ fi ọkọ rẹ̀ sílẹ̀." 11 Ṣùgbọ́n ó fi ọkọ rẹ̀ sílẹ̀; jẹ́ ó láìní ọkọ mọ́, bẹ́̀ kọ́, ó ọkọ rẹ̀ làjà, ọkọ ó ṣe aya rẹ̀ sílẹ̀.

12 7.12: 2Kọ 11.17. Mo fẹ́ fi àwọn ìmọ̀ràn kan kún ún fún un yín, í ṣe àṣẹ láti ̀dọ̀ Olúwa. arákùnrin fẹ́ aya gbàgbọ́, aya náà á fẹ́ dúró ọkọ náà, ọkọ náà í ṣe onígbàgbọ́ gbọdọ̀ kọ̀ ́ sílẹ̀. 13 ó jẹ́ obìnrin fẹ́ ọkọ gbàgbọ́, ṣùgbọ́n ọkọ náà ń fẹ́ obìnrin yìí dúró òun, aya náà gbọdọ̀ kọ̀ ́ sílẹ̀. 14 Nítorí ó ṣe é ṣe a ọkọ gba Kristi gbọ́ súnmọ́ Ọlọ́run nípa aya í ṣe onígbàgbọ́, a le ìyàwó gba Kristi gbọ́ súnmọ́ Ọlọ́run nípa ọkọ í ṣe onígbàgbọ́. ṣe bẹ́̀, àwọn ọmọ wọn yóò jẹ́ aláìmọ́. Ṣùgbọ́n wọn kọ ara wọn sílẹ̀, ó ṣe é ṣe àwọn ọmọ wọn di mímọ́.

15 Ṣùgbọ́n ̀yin i ṣe aláìgbàgbọ́ náà fẹ́ láti lọ, jẹ́ ó máa lọ. Arákùnrin tàbí arábìnrin náà lábẹ́ ìdè mọ́; Ọlọ́run ti láti gbé àlàáfíà. 16 7.16: 1Pt 3.1.Báwo ni ̀yin aya ṣe le mọ̀ bóyá ̀yin ni yóò gba ọkọ yín ? Bákan náà ni a nípa ọkọ í ṣe onígbàgbọ́ , ìdánilójú aya aláìgbàgbọ́ le yípadà láti di onígbàgbọ́ nípa dídúró ti ọkọ.

̀rọ̀ nípa ipò ti a wa

17 7.17: Ro 12.3; 1Kọ 14.33; 2Kọ 8.18; 11.28. Ṣùgbọ́n jẹ́ olúkúlùkù máa gbé ìgbé ayé Ọlọ́run ń fẹ́ yín fún, àti nínú èyí Olúwa é . Ìlànà àti òfin mi fún gbogbo ìjọ ni èyí. 18 7.18: Ap 15.1-8.Ǹjẹ́ ọkùnrin kan ha ti kọlà nígbà a é? ó ṣe di aláìkọlà. Ǹjẹ́ ọkùnrin kan ha ti kọlà nígbà a é? ó ma ṣe kọlà. 19 7.19: Ga 5.6; 6.15; Ro 2.25.Ìkọlà jẹ́ nǹkan àti àìkọlà jẹ́ nǹkan, ṣe pípa òfin Ọlọ́run mọ́. 20 Ó yẹ ẹnìkọ̀̀kan máa ṣe iṣẹ́ ó ń ṣe tẹ́lẹ̀, Ọlọ́run é sínú ìgbàgbọ́ nínú Kristi.

21 Ǹjẹ́ ẹrú ni ́ nígbà ti a ́? ṣe á . Ṣùgbọ́n ìwọ le di òmìnira, kúkú ṣe èyí . 22 7.22: Jh 8.32,36.ó jẹ́ ẹrú, ti Olúwa , rántí Kristi ti sọ ́ di òmìnira kúrò lọ́wọ́ agbára búburú ti ̀ṣẹ̀. ó ti ̀ nítòótọ́ ó ti di òmìnira, ó ti di ẹrú Kristi. 23 7.23: 1Kọ 6.20.A ti yín iye kan, nítorí náà ṣe di ẹrú ènìyàn. 24 Ará, jẹ́ olúkúlùkù ènìyàn, nínú èyí a é, ó dúró nínú ̀kan náà pẹ̀Ọlọ́run.

̀rọ̀ nípa àwọn àpọ́n

25 Ṣùgbọ́n nípa ti àwọn wúńdíá, èmi àṣẹ kankan láti ̀dọ̀ Olúwa, ṣùgbọ́n mo fún yín ìdájọ́ ẹni ó àánú Olúwa gbà láti jẹ́ olódodo. 26 Nítorí náà mo èyí dára nítorí wàhálà ìsinsin yìí, èyí ni o dára fún ènìyàn ó o ṣe . 27 Ǹjẹ́ ó ti ṣe ẹlẹ́rìí láti fẹ́ ìyàwó. ṣe kọ ara yín sílẹ̀, nítorí èyí mo yìí. Ṣùgbọ́n o ìgbéyàwó, tàbí fẹ́ ọkọ, ṣe sáré láti ṣe bẹ́̀ lákokò yìí. 28 Ṣùgbọ́n ìwọ gbé ìyàwó ìwọ dẹ́ṣẹ̀, a gbé wúńdíá ìyàwó òun dẹ́ṣẹ̀. Ṣùgbọ́n irú àwọn ó gbé ìyàwó yóò dojúkọ ̀pọ̀lọpọ̀ wàhálà nípa ti ara, ṣùgbọ́n èmi fẹ́ a yín .

29 7.29: Ro 13.11-12; 1Kọ 7.31. Òun ti mo ń ará, ni kúkúrú ni àkókò, láti ìsinsin yìí lọ, ẹni ó ni aya ó dàbí ẹni ; 30 àwọn ń sọkún, ẹni wọn sọkún , àti àwọn ń yọ̀ ẹni wọn yọ̀ , àti àwọn ń ẹni wọn , 31 àti àwọn ń lo ohun ayé yìí, ẹni ṣe àṣejù nínú wọn: nítorí ìgbà ayé yìí ń kọjá lọ.

32 7.32: 1Tm 5.5. Nínú gbogbo nǹkan ń ṣe ni mo fẹ́ sọ ara yín di òmìnira lọ́wọ́ àníyàn. Ọkùnrin ìyàwó le lo àkókò rẹ̀ láti fi ṣiṣẹ́ fún Olúwa, yóò ronú ó ti ṣe le tẹ́ Olúwa lọ́rùn. 33 Ṣùgbọ́n ọkùnrin ó ṣe ìgbéyàwó le ṣe bẹ́̀, nítorí ó láti ronú àwọn nǹkan rẹ̀ nínú ayé yìí àti ó ti ṣe le tẹ́ aya rẹ̀ lọ́rùn, 34 dájúdájú, ìfẹ́ rẹ̀ pín ̀méjì. Bákan náà fún obìnrin a gbé ìyàwó àti wúńdíá. Obìnrin ì délé ọkọ a máa tọ́ohun ṣe ti Olúwa, òun jẹ́ mímọ́ ara àti ̀. Ṣùgbọ́n ọmọbìnrin a ti gbé níyàwó, a máa ṣe ìtọ́ohun ṣe ti ayé, yóò ti ṣe le tẹ́ ọkọ rẹ̀ lọ́rùn. 35 Mo ń sọ èyí fún àǹfààní ara yín í ṣe láti yín lẹ́kun ṣùgbọ́n ̀yin gbé ̀ó tọ́ máa sin Olúwa láìsí ìyapa ọkàn.

36 Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni òun ṣe ohun ó yẹ wúńdíá rẹ̀ ti ìpòùngbẹ rẹ si pọ si, ó tọ́ bẹ́̀, jẹ́ ó ṣe ó fẹ́, òun dẹ́ṣẹ̀, jẹ́ wọn gbé ìyàwó. 37 Ṣùgbọ́n ẹni ó dúró ṣinṣin ni ọkàn rẹ̀, àìgbọdọ̀ ṣe, ṣùgbọ́n ó agbára lórí ìfẹ́ ara rẹ̀, ó ti pinnu ọkàn rẹ̀ , òun ó pa wúńdíá ọmọbìnrin òun mọ́, yóò ṣe rere. 38 Bẹ́̀ ẹni ó fi wúńdíá ọmọbìnrin fún ni ìgbéyàwó, ó ṣe rere; ṣùgbọ́n ẹni fi fún ni ìgbéyàwó ṣe rere jùlọ.

39 7.39: Ro 7.2. A fi òfin obìnrin níwọ̀n ìgbà òun pẹ̀ọkọ rẹ̀ láààyè, ọkọ rẹ̀ , ó òmìnira láti ṣe ìgbéyàwó pẹ̀ọkùnrin mìíràn, ó ú ó gbọdọ̀ jẹ́ ti Olúwa. 40 7.40: 1Kọ 7.25.Ṣùgbọ́n nínú èrò tèmi obìnrin náà yóò ayọ̀ púpọ̀, ṣe ìgbéyàwó mìíràn mọ́. Mo mo ń fún un yín ìmọ̀ràn láti ̀dọ̀ ̀Ọlọ́run nígbà mo ń sọ nǹkan wọ̀nyí.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-