Publicidade

Cânticos 4

Olùfẹ́

1 Báwo ni ìwọ ti lẹ́olólùfẹ́ mi!

Háà, ìwọ jẹ́ arẹwà!

Ìwọ ojú àdàbà lábẹ́ ìbòjú rẹ

irun rẹ ́ lójú ̀wọ́ ewúrẹ́.

ó sọ̀kalẹ̀ lórí òkè Gileadi.

2 Eyín rẹ̀ funfun i irun àgbò

ó gòkè láti ibi ìwẹ̀;

olúkúlùkù wọn èjìrẹ́;

̀kan nínú wọn ó da dúró.

3 Ètè rẹ dàbí òwú òdòdó;

ẹnu rẹ̀ dùn.

̀rẹ̀kẹ́ rẹ dàbí ̀pomegiranate

lábẹ́ ìbòjú rẹ.

4 Ọrùn rẹ dàbí ilé ìṣọ́ Dafidi,

a kọ́ pẹ̀ìhámọ́ra;

lórí rẹ̀ ni a fi ẹgbẹ̀rún (1,000) àpáta kọ́,

gbogbo wọn jẹ́ àṣà àwọn alágbára.

5 Ọmú rẹ̀ méjèèjì dàbí abo egbin méjì

wọ́n jẹ́ ìbejì

ń jẹ láàrín ìtànná ewéko lílì.

6 Títí ọjọ́ yóò fi rọ̀

òjìji yóò fi lọ,

èmi yóò lọ orí òkè ńlá òjìá

àti òkè kékeré tùràrí.

7 Gbogbo ara rẹ jẹ́ kìkì ẹwà, olólùfẹ́ mi;

ṣí àbàwọ́n lára rẹ.

8 a lọ kúrò Lebanoni, ìyàwó mi,

ki a lọ kúrò Lebanoni.

Àwa láti orí òkè Amana,

láti orí òkè ti Seniri, àti téńté Hermoni,

láti ibi ihò àwọn kìnnìún,

láti orí òkè ńlá àwọn ẹkùn.

9 Ìwọ ti gba ọkàn mi, arábìnrin mi, ìyàwó mi;

ìwọ ti gba ọkàn mi

pẹ̀ìwò ̀̀kan ojú rẹ,

pẹ̀̀kan nínú ìlẹ̀kẹ̀ ọrùn rẹ.

10 Ìfẹ́ rẹ ti dùn , arábìnrin mi, ìyàwó mi!

Ìfẹ́ rẹ tu ni lára ju ọtí wáìnì lọ,

òórùn ìkunra rẹ ju òórùn gbogbo tùràrí lọ!

11 Ètè rẹ ń kan dídùn afárá oyin, ìyàwó mi;

wàrà àti oyin lábẹ́ ahọ́n rẹ.

Òórùn aṣọ rẹ dàbí òórùn Lebanoni.

12 Arábìnrin mi ni ọgbà a sọ, arábìnrin mi, ìyàwó mi;

ìsun a mọ́, orísun a fi èdìdì .

13 Ohun ̀gbìn rẹ àgbàlá pomegiranate ni

ti òun ti àṣàyàn èso; kipiresi àti nadi,

14 nadi àti Safironi,

kalamusi àti kinamoni,

àti gbogbo igi olóòórùn dídùn,

òjìá àti aloe

pẹ̀irú wọn.

15 Ìwọ ni ọgbà orísun, kànga omi ìyè,

ìṣàn omi láti Lebanoni .

Olólùfẹ́

16 ìwọ afẹ́fẹ́ àríwá

o , afẹ́fẹ́ gúúsù!

Fẹ́ lórí ọgbà mi,

àwọn òórùn dídùn inú rẹ rùn jáde.

Jẹ́ olùfẹ́ mi sínú ọgbà a rẹ̀

ó jẹ àṣàyàn èso rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-