Pular para o conteúdo
Publicidade

Salvador

Por Bíblia Online

Jesus é o Salvador do mundo. Desde a manjedoura até a cruz e a ressurreição, toda a Escritura aponta para Aquele que veio buscar e salvar o que se havia perdido.

O Salvador nasceu

Na plenitude dos tempos, Deus enviou seu Filho ao mundo. O anjo declarou: 'Hoje vos nasceu um Salvador, que é Cristo, o Senhor.'

Nítorí a ti Olùgbàlà fún yín lónìí ìlú Dafidi, í ṣe Kristi Olúwa.

Ẹni , o tilẹ̀ jẹ́ ìrísí Ọlọ́run,

á ohun ìbá fi ìwọra gbámú láti Ọlọ́run dọ́gba.

Ṣùgbọ́n ó bọ́ ògo rẹ̀ sílẹ̀,

ó àwọ̀ ìránṣẹ́,

a ṣe é ni àwòrán ènìyàn.

Ó àwòrán ènìyàn,

ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀,

o tẹríba títí de ojú ikú,

àní ikú lórí àgbélébùú.

"Ṣùgbọ́n Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ̀,

ẹni jáde láti ilẹ̀ Ejibiti .

Ìwọ̀ yóò mọ ọlọ́run mìíràn àfi èmi

olùgbàlà mìíràn lẹ́yìn mi.

O sacrifício redentor

Jesus deu a própria vida por nós. Ele é a propiciação pelos nossos pecados e o autor da salvação eterna para todos os que lhe obedecem.

Òun ètùtù fún ̀ṣẹ̀ wa, í tilẹ̀ ṣe fún tiwa nìkan ṣùgbọ́n fún ̀ṣẹ̀ gbogbo aráyé.

Nínú èyí ni ìfẹ́ , í ṣe àwa fẹ́ Ọlọ́run, ṣùgbọ́n òun fẹ́ , ó rán Ọmọ rẹ̀ láti jẹ́ ètùtù fún ̀ṣẹ̀ wa.

Ǹjẹ́, nígbà àwa ̀, a wa, ba Ọlọ́run làjà nípa ikú Ọmọ rẹ̀, mélòó mélòó, nígbà a ìjà tan, ni a ó gbà nípa ìyè rẹ̀.

Níwọ̀n ̀yin ti mọ̀ a fi ohun ìdíbàjẹ́ yín padà, fàdákà tàbí wúrà kúrò nínú ìwà asán yín, ̀yin ti jogún láti ̀dọ̀ àwọn baba yín. Ṣùgbọ́n pẹ̀̀jẹ̀ iyebíye, i ti ̀dọ́-àgùntàn ti lábùkù, lábàwọ́n, àní, ̀jẹ̀ Kristi.

Nínú rẹ̀ ni àwa ìràpadà gba nípa ̀jẹ̀ rẹ̀ àti ìdáríjì àwọn ̀ṣẹ̀ wa, ìbámu pẹ̀ọrọ̀ oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run

A ti kàn mọ́ àgbélébùú pẹ̀Kristi, èmí láààyè mọ́, ṣùgbọ́n Kristi ń gbé inú mi wíwà mo láààyè nínú ara, mo láààyè nínú ìgbàgbọ́ Ọmọ Ọlọ́run, ẹni o fẹ́ mi, ó fi òun tìkára rẹ̀ fún mi.

O caminho da salvação

Jesus é o mediador da nova aliança. Ele vive para interceder por nós e pode salvar perfeitamente todos os que se achegam a Deus por meio dele.

a ti sọ di pípé, o wa di orísun ìgbàlà àìnípẹ̀kun fún gbogbo àwọn ó ń gbọ́ tirẹ̀,

Nítorí náà ó le gbà wọ́n pẹ̀títí òpin, ẹni ó tọ Ọlọ́run nípasẹ̀ rẹ̀, nítorí o ń bẹ láààyè títí láé láti máa bẹ̀bẹ̀ fún wọn.

Àti nítorí èyí ni ó ṣe jẹ́ alárinà májẹ̀tuntun ikú ti ń bẹ fún ìdáǹdè àwọn ìrékọjá ti o lábẹ́ májẹ̀ìṣáájú, àwọn a ti ìlérí ogún àìnípẹ̀kun gbà.

a máa wo Jesu Olùpilẹ̀ṣẹ̀ àti aláṣepé ìgbàgbọ́ wa; ẹni nítorí ayọ̀ a gbé ka iwájú rẹ, o faradà àgbélébùú láìka ìtìjú , ó jókòó lọ́wọ́ ̀tún ìtẹ́ Ọlọ́run.

Gbogbo ènìyàn ni ó ṣá ti ṣẹ̀, wọ́n kùnà ògo Ọlọ́run, àwọn ẹni a ń láre lọ́fẹ̀́ nípa oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀, nípa ìdáǹdè ó nínú Kristi Jesu.

Ṣùgbọ́n mo ri ìrànlọ́wọ́ gbà láti ́dọ̀ Ọlọ́run, mo dúró títí ó fi di òní, mo ń jẹ́rìí fún èwe àti àgbà, èmi sọ ohun mìíràn ṣe ohun àwọn wòlíì àti Mose , yóò ṣẹ. , Kristi yóò jìyà, àti òun ni yóò jẹ́ ẹni àkọ́kọ́ láti jíǹde kúrò nínú òkú, òun ni yóò kéde ìmọ́lẹ̀ fún àwọn ènìyàn àti fún àwọn aláìgbàgbọ́."

Nígbà náà ni angẹli náà fún àwọn obìnrin náà , "ṣe bẹ̀. Mo mọ̀ ̀yin ń Jesu a kàn mọ́ àgbélébùú. Ṣùgbọ́n níhìn-ín. Nítorí ó ti jíǹde, gẹ́gẹ́ òun ti . wọlé wo ibi ti wọ́n tẹ́ .

Nítorí èmi mọ̀ olùdáǹdè mi ń bẹ láààyè

àti pe òun ni yóò dìde dúró lórí ilẹ̀ ìkẹyìn;

Seja o primeiro