Publicidade

Hebreus 7

Melkisedeki jẹ́ àlùfáà

1 Nítorí Melkisedeki yìí, ọba Salẹmu, àlùfáà Ọlọ́run ̀gá-ògo, ẹni ó pàdé Abrahamu ó ti ń padà bọ̀ láti ibi pípa àwọn ọba, ó súre fún un, 2 ẹni Abrahamu pín ìdámẹ́wàá ohun gbogbo fún. ̀èkínní orúkọ rẹ̀ túmọ̀ "ọba òdodo"; àti lẹ́yìn náà pẹ̀, "ọba Salẹmu," í ṣe "ọba àlàáfíà." 3 Láìní baba, láìní ìyá, láìní ìtàn ìran, bẹ́̀ ni ìbẹ̀rẹ̀ ọjọ́ tàbí òpin ọjọ́ ayé; ṣùgbọ́n a ṣe é Ọmọ Ọlọ́run; ó àlùfáà títí.

4 Ǹjẹ́ gbà á ọkùnrin yìí ti pọ̀ , ẹni Abrahamu baba ńlá fi ìdámẹ́wàá nínú àwọn àṣàyàn ìkógun fún. 5 Àti nítòótọ́ àwọn ó jẹ́ ọmọ Lefi, o gba oyè àlùfáà, wọ́n àṣẹ láti máa gba ìdámẹ́wàá lọ́wọ́ àwọn ènìyàn gẹ́gẹ́ òfin, èyí yìí, lọ́wọ́ àwọn arákùnrin wọn, ó tilẹ̀ ti jẹ́ , wọn ti inú Abrahamu jáde. 6 Ṣùgbọ́n òun ẹni a tilẹ̀ pìtàn ìran rẹ̀ láti ̀dọ̀ wọn , gba ìdámẹ́wàá lọ́wọ́ Abrahamu, ó súre fún ẹni ó gba ìlérí, 7 láìsí ìjiyàn rárá ẹni ẹni à ń súre fún láti ̀dọ̀ ẹni ó ju ni. 8 Ni apá kan, àwọn ẹni kíkú gba ìdámẹ́wàá; ṣùgbọ́n níbẹ̀, ẹni a jẹ́rìí rẹ̀ o ń bẹ láààyè . 9 Àti a ti , Lefi pàápàá ń gba ìdámẹ́wàá, ti san ìdámẹ́wàá nípasẹ̀ Abrahamu. 10 Nítorí o à ń bẹ inú baba rẹ̀, nígbà ti Melkisedeki pàdé rẹ̀.

Jesu fẹ́ràn Melkisedeki

11 Ǹjẹ́ ìbá ṣe pípé ń bẹ nípa oyè àlùfáà Lefi (nítorí lábẹ́ rẹ̀ ni àwọn ènìyàn gba òfin), kín ni ó tún mọ́ àlùfáà mìíràn ìbá fi dìde títẹ̀àpẹẹrẹ Melkisedeki, a si títẹ̀àpẹẹrẹ Aaroni? 12 Nítorí a ti ń pààrọ̀ iṣẹ́ àlùfáà, a ṣàì máa pààrọ̀ òfin. 13 Nítorí ẹni à ń sọ̀rọ̀ nǹkan wọ̀nyí nípa rẹ̀ jẹ́ ̀mìíràn, láti inú èyí ẹnikẹ́ni jọ́sìn níbi pẹpẹ. 14 Nítorí ó hàn gbangba láti inú ̀Juda ni Olúwa wa ti dìde; nípa ̀yìí Mose sọ ohunkóhun ti àwọn àlùfáà. 15 Ó tún hàn gbangba ju bẹ́̀ lọ ó ti jẹ àlùfáà mìíràn dìde àpẹẹrẹ ti Melkisedeki. 16 Èyí a fi jẹ́, í ṣe gẹ́gẹ́ ìlànà òfin nípa ti ara, ṣe nípa agbára ti ìyè àìlópin. 17 Nítorí a jẹ́rìí :

"Ìwọ ni àlùfáà títí láé

ipasẹ̀ ti Melkisedeki."

18 Nítorí a òfin ìṣáájú kúrò nítorí àìlera àti àìlérè rẹ̀. 19 (Nítorí òfin ohunkóhun ), a ìrètí ó dára nípa èyí àwa ń súnmọ́ Ọlọ́run.

20 Níwọ́n ó ti ṣe í ṣe àìbúra ni. Nítorí àwọn àlùfáà tẹ́lẹ̀ jẹ oyè láìsí ìbúra, 21 ṣùgbọ́n ti òun jẹ́ pẹ̀ìbúra nígbà Ọlọ́run fún un ,

"Olúwa búra,

yóò padà:

Ìwọ ni àlùfáà kan títí láé.’ "

22 Níwọ́n bẹ́̀ ni Jesu ti di onígbọ̀wọ́ májẹ̀ó dára .

23 Àti nítòótọ́ àwọn púpọ̀ a ti fi jẹ àlùfáà, nítorí wọn títí nítorí ikú. 24 Ṣùgbọ́n òun, nítorí o títí láé, ó oyè àlùfáà a rọ̀ ipò. 25 Nítorí náà ó le gbà wọ́n pẹ̀títí òpin, ẹni ó tọ Ọlọ́run nípasẹ̀ rẹ̀, nítorí o ń bẹ láààyè títí láé láti máa bẹ̀bẹ̀ fún wọn.

26 Nítorí irú olórí àlùfáà bẹ́̀ ni o yẹ , mímọ́, àìlẹ́gàn, àìléèérí, a sọ́tọ̀ kúrò láàrín àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀, a gbéga ju àwọn ̀run lọ. 27 Ẹni láti máa ẹbọ lójoojúmọ́, àwọn olórí àlùfáà, fún ̀ṣẹ̀ ti ara rẹ̀ náà, àti lẹ́yìn náà fún àwọn ènìyàn; nítorí èyí ni ó ṣe lẹ́̀kan ṣoṣo, nígbà ó fi ara rẹ̀ ẹbọ. 28 Nítorí òfin a máa fi àwọn ènìyàn ó àìlera jẹ olórí àlùfáà; ṣùgbọ́n nípa ̀rọ̀ ti ìbúra, ó ṣe lẹ́yìn òfin, ó fi ọmọ jẹ; ẹni a sọ di pípé títí láé.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-