Publicidade

Hebreus 5

1 Nítorí olórí àlùfáà kọ̀̀kan a yàn nínú àwọn ènìyàn, a fi jẹ nítorí iṣẹ́ ìsìn àwọn ènìyàn Ọlọ́run láti máa ̀bùn àti ẹbọ nítorí ̀ṣẹ̀. 2 Ẹni ó ṣe jẹ́́jẹ́ pẹ̀àwọn aláìmòye, ó àwọn ó ti yapa kẹ́dùn, nítorí a fi àìlera òun náà pẹ̀. 3 Nítorí ìdí èyí ni ó ṣe yẹ, ó ti ń ẹbọ nítorí ̀ṣẹ̀ fún àwọn ènìyàn rẹ̀, bẹ́̀ pẹ̀ń ṣe fún ara rẹ̀ náà. 4 Kọ ẹni o gba ọlá yìí fún ara rẹ̀, ṣe ẹni a láti ̀dọ̀ Ọlọ́run gẹ́gẹ́ a ti pe Aaroni.

5 Bẹ́̀ ni Kristi pẹ̀ṣe ara rẹ̀ lógo láti jẹ́ olórí àlùfáà; ṣe ẹni o fún ún ,

"Ìwọ ni ọmọ mi,

lónìí ni mo ."

6 ó ti pẹ̀ibòmíràn ,

"Ìwọ ni àlùfáà títí láé

ipasẹ̀ Melkisedeki."

7 ìgbà ọjọ́ Jesu nínú ayé, ó fi ìkérora rara àti omijé gbàdúrà, ó bẹ̀bẹ̀ lọ́dọ̀ ẹni ó gbà á sílẹ̀ lọ́wọ́ ikú, a gbóhùn rẹ̀ nítorí ó ̀ìbẹ̀Ọlọ́run rẹ̀. 8 òun tilẹ̀ ń ṣe Ọmọ Ọlọ́run, síbẹ̀ ó kọ́ ìgbọ́ran nípa ohun ó jìyà rẹ̀. 9 a ti sọ di pípé, o wa di orísun ìgbàlà àìnípẹ̀kun fún gbogbo àwọn ó ń gbọ́ tirẹ̀, 10 a yàn olórí àlùfáà láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ipasẹ̀ Melkisedeki.

Ìkìlọ̀ lórí ṣíṣubú kúrò nínú ìgbàgbọ́

11 Nípa èyí àwa ohun púpọ̀ láti sọ, ó ṣòro láti túmọ̀, nítorí yigbì gbígbọ́. 12 Nítorí báyìí ó ti yẹ jẹ́ olùkọ́ni, tún ẹni ẹnìkan yóò máa kọ́ ni ìbẹ̀rẹ̀ ìpìlẹ̀ ̀kọ́ àwọn ̀rọ̀ Ọlọ́run, tún di irú àwọn ó mu wàrà, wọn fẹ́ oúnjẹ líle. 13 Nítorí olúkúlùkù ẹni ń mu wàrà jẹ́ aláìlóye ̀rọ̀ òdodo, nítorí ọmọ ọwọ́ ni. 14 Ṣùgbọ́n oúnjẹ líle fún àwọn ó dàgbà, àwọn ẹni nípa ìrírí, wọn ń lo ọgbọ́n wọn láti fi ìyàtọ̀ sáàrín rere àti búburú.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-