Publicidade

1 Coríntios 1

1 Paulu, ẹni ti a láti jẹ́ aposteli Kristi Jesu nípa ìfẹ́ Ọlọ́run àti Sostene arákùnrin wa,

2 ìjọ ènìyàn Ọlọ́run ni Kọrinti, àwọn ti a sọ di mímọ́ nínú Kristi Jesu àti àwọn ti a láti jẹ́ mímọ́ pẹ̀gbogbo ènìyàn ni ibikíbi ti ń pe orúkọ Olúwa wa Jesu Kristi ẹni ti ń ṣe Olúwa tiwọn àti ti àwa náà:

3 Oore-ọ̀fẹ́ àti àlàáfíà fún yín láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa àti Olúwa wa í ṣe Jesu Kristi.

Ìdúpẹ́

4 Nígbà gbogbo ni mo ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run fún oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ fi fún un yín nínú Kristi Jesu. 5 Nítorí nínú rẹ̀ ni a ti sọ yín di ọlọ́rọ̀ nínú ̀rọ̀ sísọ yín gbogbo àti nínú ìmọ̀ yín gbogbo. 6 Nítorí ̀wa nínú Kristi ni a ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ nínú yín. 7 Nítorí náà ̀yin ṣe aláìní nínú èyíkéyìí ̀bùn ̀, ̀yin ṣe ń retí ìfarahàn Olúwa wa Jesu Kristi. 8 Òun yóò yín dúró títí òpin, ̀yin ó jẹ́ aláìlábùkù ọjọ́ Olúwa wa Jesu Kristi. 9 Ọlọ́run, nípasẹ̀ ẹni ti a yín sínú ìdàpọ̀ pẹ̀Ọmọ rẹ̀ Jesu Kristi Olúwa wa, jẹ́ Olóòtítọ́.

Ìyapa nínú ìjọ Ọlọ́run

10 Mo bẹ̀ yín ̀yin ara, orúkọ Olúwa wa Jesu Kristi, gbogbo yín fohùn ṣọ̀kan ó máa ṣe ìyapa láàrín yín, àti a ṣe yín inú àti ìmọ̀ kan náà. 11 ̀yin ará mi, àwọn kan láti ilé Kloe sọ di mọ̀ fún mi ìjà ń bẹ́ láàrín yín. 12 Ohun mo ń sọ , olúkúlùkù yín ń , "Èmí tẹ̀Paulu"; "Èmi tẹ̀Apollo"; òmíràn , "Èmi tẹ̀Kefa, Peteru"; àti ẹlòmíràn , "Èmi tẹ̀Kristi."

13 Ǹjẹ́ a ha pín Kristi ? Ṣé a kan Paulu mọ́ àgbélébùú fún un yín ? Ǹjẹ́ a tẹ̀ yín bọ omi orúkọ Paulu ? 14 Inú mi dún púpọ̀ èmi tẹ ẹnikẹ́ni nínú yín bọ omi yàtọ̀ Krisipu àti Gaiusi. 15 Nítorí náà ẹni ó sọ òun ṣe ìtẹ̀bọmi orúkọ èmi fúnra ara mi. 16 (Bẹ́̀ ni, mo tún tẹ ìdílé Stefana bọ omi; lẹ́yìn èyí, èmí rántí mo tẹ ẹnikẹ́ni bọ omi mọ́ níbikíbi). 17 Nítorí Kristi rán mi láti máa ṣe ìtẹ̀bọmi, ṣùgbọ́n ó rán mi láti máa wàásù ìyìnrere: í ṣe nípa ọgbọ́n ènìyàn, a máa ṣe sọ àgbélébùú Kristi aláìlágbára.

Kristi ọgbọ́n àti agbára Ọlọ́run

18 Nítorí òmùgọ̀ ni ̀rọ̀ àgbélébùú jẹ́ àwọn ń ṣègbé, ṣùgbọ́n fún àwa a ń gbàlà ó jẹ́ agbára Ọlọ́run. 19 Nítorí a kọ ́ :

"Èmi yóò pa ọgbọ́n àwọn ọlọ́gbọ́n run,

òye àwọn olóye ni Èmi yóò sọ di asán."

20 Àwọn ọlọ́gbọ́n náà ha ? Àwọn akọ̀náà ha ? Àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ ayé yìí ha ? Ọlọ́run ha ti sọ ọgbọ́n ayé yìí di aṣiwèrè? 21 Nítorí , nínú ọgbọ́n Ọlọ́run, ayé le mọ̀ òun nípa ọgbọ́n àti ìṣeféfé wọn. Ó gba gbogbo àwọn ó gbàgbọ́ nípa ìwàásù àwọn aráyé òmùgọ̀ àti ̀rọ̀ yẹ̀yẹ́. 22 Nítorí àwọn Júù ń béèrè àmì, àwọn Helleni ń ṣàfẹ́ọgbọ́n, 23 ṣùgbọ́n àwa ń wàásù Kristi ti a kàn mọ́ àgbélébùú, òkúta ìkọ̀sẹ̀ àwọn Júù àti òmùgọ̀ fún àwọn kèfèrí. 24 Ṣùgbọ́n àwọn Ọlọ́run , àti àwọn Júù àti àwọn Giriki, Kristi ni agbára Ọlọ́run, àti ọgbọ́n Ọlọ́run. 25 Nítorí òmùgọ̀ Ọlọ́run ọgbọ́n ènìyàn lọ; àti aláìlera Ọlọ́run ni agbára ìlera ènìyàn lọ.

26 Ará, kíyèsi ohun jẹ́ nígbà a yín. í ṣe ̀pọ̀ yín jẹ ọlọ́gbọ́n nípa àgbékalẹ̀ ti ènìyàn, tàbí ̀pọ̀ nínú yín jẹ́ ènìyàn pàtàkì, bẹ́̀ ni í ṣe ̀pọ̀ nínú yín jẹ́ ọlọ́nípa ibi a gbé i. 27 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run yàn àwọn òmùgọ̀ ayé láti fi dààmú àwọn ọlọ́gbọ́n; Ọlọ́run ti yàn àwọn ohun aláìlera ayé láti fi dààmú àwọn ohun ó ni agbára. 28 Àti àwọn ohun ayé ìyìn, àti àwọn ohun a kẹ́gàn, ni Ọlọ́run ti yàn, àní àwọn ohun , láti sọ àwọn ohun ó di asán. 29 Nítorí ó ba à ẹnìkan yóò ṣògo níwájú rẹ̀. 30 Nítorí rẹ̀ ni ̀yin ṣe nínú Kristi Jesu ẹni ti ó jásí ọgbọ́n fún wa láti ̀dọ̀ Ọlọ́runèyí ń ni, òdodo, ìwà mímọ́ àti ìràpadà wa. 31 Nítorí náà, a ti kọ ́ , "Ẹni ti ó ń ṣògo ó máa ṣògo nínú Olúwa."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-