Publicidade

1 Coríntios 12

̀bùn ̀Mímọ́

1 ti ̀Mímọ́ ̀yin ará, yẹ́ jẹ́ òpè. 2 12.2: Ef 2.11-12.̀yin mọ̀ nígbà ̀yin jẹ́ kèfèrí, a yín lọ sọ́dọ̀ àwọn odi òrìṣà. 3 12.3: Ro 10.9.Nítorí náà, èmí ń sọ fún un yín ẹni ti ń sọ̀rọ̀ nípasẹ̀ ̀Ọlọ́run ó , "Ẹni ìfibú ni Jesu," àti ẹni ó sọ , "Olúwa ni Jesu," ṣe nípasẹ̀ ̀Mímọ́.

4 Ǹjẹ́ onírúurú ̀bùn ni ó , ṣùgbọ́n ̀kan náà ni o ń pín wọn. 5 Onírúurú iṣẹ́ ìránṣẹ́ ni ó , ṣùgbọ́n Ọlọ́run kan náà ni. 6 Onírúurú iṣẹ́ ìránṣẹ́ ni ó , ṣùgbọ́n Ọlọ́run kan náà ni ẹni ń ṣiṣẹ́ gbogbo wọn nínú gbogbo wọn.

7 Ṣùgbọ́n à ń fi ̀bùn ̀fún olúkúlùkù ènìyàn láti fi jèrè. 8 ̀Mímọ́ fún ẹnìkan ọgbọ́n láti fún ènìyàn nímọ̀ràn, ẹlòmíràn ̀bùn láti sọ̀rọ̀ pẹ̀ìmọ̀ ńlá. Láti ̀dọ̀ ̀Mímọ́ kan náà ni èyí ti . 9 Ó fi ̀bùn ìgbàgbọ́ fún ẹlòmíràn, ẹlòmíràn fi agbára ìwòsàn fún nípa ̀Mímọ́ kan náà. 10 12.10: 1Kọ 14.26.Ó fi agbára fún àwọn mìíràn láti ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu. Ó fún àwọn mìíràn lágbára láti sọ àsọtẹ́lẹ̀ àti láti wàásù pẹ̀ìmísí. Bákan náà fún àwọn kan lẹ́bùn láti mọ ìyàtọ̀ láàrín àwọn ̀. Ó fún àwọn ẹlòmíràn ̀bùn àti agbára láti sọ èdè wọn mọ̀. Bákan náà ó fún àwọn ẹlòmíràn lágbára láti mọ̀ àti láti túmọ̀ èdè wọn gbọ́ . 11 Àní, ̀kan ṣoṣo ń fún ni gbogbo ̀bùn àti agbára wọ̀nyí. Òun ni ẹni ń ṣe ìpinnu ̀bùn ó yẹ láti fún ẹnìkọ̀̀kan.

12 12.12: Ro 12.4. Ara jẹ́ ̀kan ó àwọn ̀púpọ̀, ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ̀ara ó pọ̀ wọ̀nyí ni ó papọ̀ láti jẹ́ ara kan ṣoṣo. Bákan náà ni ó pẹ̀ara Kristi í ṣe ìjọ. 13 12.13: Ga 3.28; Kl 3.11; Ef 2.13-18; Jh 7.37-39.Nítorí nínú ̀kan a ti bamitiisi gbogbo wa sínú ara kan, ìbá à ṣe Júù, ìbá à ṣe Giriki, ìbá à ṣe ẹrú, ìbá à ṣe òmìnira, gbogbo wa ni a mu nínú ̀Mímọ́ kan náà. 14 Bẹ́̀ ni, ara, í ṣe ̀kan ṣoṣo ṣe púpọ̀.

15 ẹsẹ̀ , "Nítorí èmi í ṣe ọwọ́, èmi í ṣe ti ara," èyí í ṣe ̀kan lára nínú ̀ara. 16 etí , "Nítorí èmi í ṣe ojú, èmi í ṣe apá kan ara," èyí le ó jẹ́ apá kan ara mọ́. 17 gbogbo ara jẹ́ ojú, níbo ni ìgbọ́ran ìbá gbé ? gbogbo ara jẹ́ etí, níbo ni ìgbóórùn ìbá gbé ? 18 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ti fi àwọn ̀ara si ara wa, ó fi ̀kọ̀̀kan ibi ó fẹ́ ó . 19 gbogbo wọn jẹ́ ̀kan ṣoṣo nínú ̀ara, níbo ni ara yóò gbé . 20 Ọlọ́run ̀ara púpọ̀, ṣùgbọ́n ara kan ṣoṣo ni.

21 ó yìí, ojú sọ fún ọwọ́ , "Èmi nílò rẹ." Bẹ́̀ ni orí le sọ fún ẹsẹ̀ , "Èmi nílò rẹ." 22 Àwọn ̀ara ó dàbí ẹni wọ́n ṣe aláìlágbára jùlọ, ó dàbí ẹni ṣe pàtàkì rárá, àwọn gan an ni a le ṣe aláìnílò. 23 Bẹ́̀ ni ̀ara a lọ́rárá ni àwa ń fi ọlá fún jùlọ. Àwọn ̀ara a ko yẹ rárá ni àwa ń fi si ipò ọlá ̀yẹ ó ga jùlọ. 24 Nítorí àwọn ibi ó ̀yẹ ara wa nílò ìtọ́̀tọ̀. Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ti pa gbogbo ̀ara pọ̀ ṣọ̀kan lọ́kan, ó ti fi ̀yẹ ga jùlọ fún ibi ó ṣe aláìní. 25 ó ṣe ìyàtọ̀ nínú ara, ṣùgbọ́n àwọn ̀ara le máa jẹ́ olùrànlọ́wọ́ fún ara wọn. 26 ̀ara kan ń jìyà, gbogbo àwọn ̀ara ìyókù a máa a pín nínú ìyà náà. a bu ọlá fún ̀ara kan, gbogbo ̀ara ìyókù a máa a yọ̀.

27 12.27: Ef 1.23; 4.12; Kl 1.18,24; Ef 5.30; Ro 12.5. Gbogbo yín jẹ́ ara Kristi, ẹnìkọ̀̀kan yín jẹ́ ̀ara ̀tọ̀̀tọ̀ nínú ara Kristi. 28 12.28: Ef 4.11; 2.20; 3.5.Ọlọ́run gbé àwọn mìíràn kalẹ̀ nínú ìjọ, èkínní àwọn aposteli, èkejì àwọn wòlíì, ̀kẹta àwọn olùkọ́ni, lẹ́yìn náà, àwọn ń ṣiṣẹ́ ìyanu, lẹ́yìn náà àwọn ó ̀bùn ìmúláradá, àwọn olùrànlọ́wọ́ àti àwọn agbani nímọ̀ràn, àwọn ń sọ onírúurú èdè. 29 Ǹjẹ́ gbogbo ènìyàn ni ó jẹ́ aposteli bi? Tàbí gbogbo ènìyàn ni wòlíì ? Ṣe gbogbo ènìyàn olùkọ́ni? Ṣé gbogbo ènìyàn agbára láti ṣe iṣẹ́ ìyanu ? 30 Ṣé gbogbo ènìyàn wonisàn ? Rárá. Ǹjẹ́ gbogbo wa ni Ọlọ́run fún ̀bùn láti le sọ̀rọ̀ èdè a ì ì gbọ́ ? Ṣé ẹnikẹ́ni túmọ̀ èdè wọ́n sọ àwọn ènìyàn ? 31 Ṣùgbọ́n, máa fi ìtara ṣàfẹ́̀bùn ti ó tóbi .

Síbẹ̀ èmi o fi ̀kan ó tayọ rékọjá hàn yín.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-