Publicidade

1 Coríntios 16

Ìkójọpọ̀ fún àwọn ènìyàn Ọlọ́run

1 16.1: Ap 24.17. Ǹjẹ́ ti ìdáwó fún àwọn ènìyàn mímọ́, mo fún àwọn ìjọ Galatia, bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ṣe. 2 16.2: Ap 20.7; 2Kọ 9.4-5.ọjọ́ kìn-ín-ní ̀sẹ̀, olúkúlùkù yín fi sínú ìṣúra lọ́dọ̀ ara rẹ̀ ni apá kan, gẹ́gẹ́ Ọlọ́run ti ṣe rere fún ún, ki ó ṣe si ìkójọ nígbà mo . 3 16.3: 2Kọ 8.18-19.Àti nígbà ti mo , àwọn ẹni yàn, àwọn ni èmi ó rán láti ̀bùn yín gòkè lọ si Jerusalẹmu. 4 ó yẹ èmí lọ pẹ̀, wọn ó mi lọ.

Ìbéèrè ti ara ẹni

5 16.5: Ro 15.26; Ap 19.21. Ṣùgbọ́n èmi yóò tọ̀ yin , nígbà èmí ti kọjá láàrín Makedonia: nítorí èmi yóò kọjá láàrín Makedonia. 6 Bóyá èmi ó dúró pẹ̀yín, tàbí n tilẹ̀ lo àkókò òtútù, ki ̀yin sìn ni ̀àjò , níbikíbi mo ń lọ. 7 16.7: Ap 18.21.Nítorí èmi fẹ́ kan ri yín èmi ṣe bẹ́̀ kọjá lọ; nítorí èmi ń retí àti dúró lọ́dọ̀ yín díẹ̀, Olúwa fẹ́. 8 16.8: Ap 18.19.Ṣùgbọ́n èmi yóò dúró ni Efesu títí Pentikosti. 9 16.9: Ap 19.9.Nítorí ìlẹ̀kùn ńlá láti ṣe iṣẹ́ gidi ṣí sílẹ̀ fún , ̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn ̀ń bẹ.

10 16.10: Ap 16.1. Ǹjẹ́ Timotiu , jẹ́ ó lọ́dọ̀ yín láìbẹ̀, nítorí òun ń ṣé iṣẹ́ Olúwa, èmi pẹ̀ti ń ṣe. 11 Nítorí náà ẹnikẹ́ni ṣe kẹ́gàn rẹ̀. Ṣùgbọ́n sín ín jáde lọ́àjò ni àlàáfíà, òun tọ̀ ; nítorí èmí ń fi ojú ̀fún wíwá rẹ̀ pẹ̀àwọn arákùnrin.

12 16.12: Ap 18.24. Ṣùgbọ́n ti Apollo arákùnrin wa, mo bẹ̀ ́ púpọ̀ láti tọ̀ yín pẹ̀àwọn arákùnrin, ṣùgbọ́n í ṣe ìfẹ́ rẹ̀ rárá láti nísinsin yìí, ṣùgbọ́n òun yóò nígbà ààyè ṣí sílẹ̀ fún un.

13 16.13: Sm 31.24; Ef 6.10. máa ṣọ́ra, dúró ṣinṣin nínú ìgbàgbọ́, ṣe bi ọkùnrin ó ìgboyà, jẹ́ alágbára. 14 máa ṣe ohun gbogbo nínú ìfẹ́.

15 Ǹjẹ́ mo bẹ̀ yín ará, ṣá mọ ilé Stefana , àwọn ni ẹni àkọ́kọ́ gba Jesu Akaia, àti , wọn fi ará wọn fún iṣẹ́ ìránṣẹ́ àwọn ènìyàn mímọ́. 16 ̀yin tẹríba fún irú àwọn báwọ̀nyí, àti fún olúkúlùkù olùbáṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀wa ó ń ṣe làálàá. 17 Mo láyọ̀ fún wíwá Stefana àti Fortunatu àti Akaiku, nítorí èyí ó nípá yín wọ́n ti fi kún un. 18 Nítorí wọ́n tu ̀lára àti tiyín: nítorí náà, máa gba irú àwọn ti ó bẹ́̀.

Ìkíni ìkẹyìn

19 16.19: Ap 18.2; Ro 16.5. Àwọn ìjọ ni Asia í yín.

Akuila àti Priskilla í yín púpọ̀ nínú Olúwa, pẹ̀ìjọ ó ni ilé wọn.

20 16.20: Ro 16.16. Gbogbo àwọn arákùnrin í yín.

fi ìfẹnukonu mímọ́ ara yín.

21 16.21: Kl 4.18; Ga 6.11; 2Tẹ 3.17. Ìkíni ti èmi Paulu, láti ọwọ́ èmi tìkára mi .

22 16.22: Ro 9.3. ẹnikẹ́ni ìfẹ́ Jesu Kristi Olúwa, jẹ́ ó ẹni ìfibú. Máa bọ Olúwa wa!

23 16.23: Ro 16.20. Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa ó pẹ̀yín!

24 Ìfẹ́ mi pẹ̀gbogbo yín nínú Kristi Jesu. Àmín.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-