Publicidade

1 Coríntios 3

Lórí ìyapa nínú ìjọ

1 3.1: Ro 7.14; Hb 5.13. Ará, èmí le yín sọ̀rọ̀ àwọn í ṣe ti ̀, ṣe àwọn ti í ṣe ti ara, àní àwọn ọmọ ọwọ́ nínú Kristi. 2 3.2: Hb 5.12-13; 1Pt 2.2.Wàrà ni mo ti fi bọ́ yín, í ṣe oúnjẹ; nítorí í le gbà á nísinsin yìí náà, í le gbà a. 3 Nítorí ̀yin jẹ́ ti ara síbẹ̀. Nítorí, níwọ̀n owú jíjẹ àti ìjà ṣe láàrín ara yín, ̀yin ha ṣe ti ayé ? ̀yin ha ṣe ènìyàn lásán ? 4 3.4: 1Kọ 1.12.Ǹjẹ́ ̀yin í ṣe ènìyàn lásán ? Níwọ́n ìgbà ba ń sọ , "Èmi ń tẹ̀Paulu," àti ti ẹlòmíràn tún , "Èmi ń tẹ̀Apollo."

5 3.5: 2Kọ 6.4; Ef 3.7; Kl 1.25. gbogbo rẹ̀ lọ, ni Apollo ha jẹ́, kín ni Paulu jẹ́, àwọn ìránṣẹ́ lásán, nípasẹ̀ ẹni ̀yin gbàgbọ́, gẹ́gẹ́ Olúwa ti fi fún olúkúlùkù. 6 3.6: Ap 18.4-11,24-27; 1Kọ 1.12.Èmi gbìn, Apollo ń bomirin; ṣùgbọ́n Ọlọ́run ni ń ìbísí . 7 Ǹjẹ́ í ṣe ẹni ó ń gbìn nǹkan kan, bẹ́̀ ni í ṣe ẹni ń bomirin; ṣe Ọlọ́run ó ń ìbísí . 8 Ẹni ó ń gbìn àti ẹni ó ń bu omi rín ìrònú kan àti èrèdí kan, ó tilẹ̀ jẹ́ ẹnìkọ̀̀kan wa yóò gba èrè tirẹ̀, gẹ́gẹ́ ó ti ṣe é kárakára . 9 3.9: Isa 61.3; Ef 2.20-22; 1Pt 2.5.A ń Ọlọ́run ṣiṣẹ́ pọ̀ ni, ̀yin pàápàá jẹ́ ọgbà ohun ̀gbìn fún Ọlọ́run, í ṣe fún wa, ilé Ọlọ́run ni yín, í ṣe ilé tiwa.

10 3.10: Ro 12.3; 1Kọ 15.10. Nípa oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run fi fún mi, gẹ́gẹ́ ọlọ́gbọ́n ̀mọ̀, mo ti fi ìpìlẹ̀ ilé lélẹ̀, ẹlòmíràn ń mọ e, ṣùgbọ́n olúkúlùkù kíyèsára yóò ṣe mọ ́n e. 11 3.11: Ef 2.20.Nítorí ẹlòmíràn le fi ìpìlẹ̀ tòótọ́ mìíràn lélẹ̀ ju èyí a fi lélẹ̀ àní Jesu Kristi ni ìpìlẹ̀ náà. 12 Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni fi wúrà, fàdákà, òkúta olówó-iyebiye, igi, koríko, àgékù koríko mọ orí ìpìlẹ̀ yìí. 13 3.13: 2Tẹ 1.7-10.Iṣẹ́ olúkúlùkù ènìyàn yóò hàn, nítorí ọjọ́ náà yóò fi í hàn, nítorí nínú iná ni a ó ti fihàn, iná náà yóò dán irú iṣẹ́ èyí olúkúlùkù ṣe . 14 iṣẹ́ ẹnikẹ́ni ṣe lórí rẹ̀ dúró, òun yóò gba èrè rẹ̀. 15 3.15: Jb 23.10.iṣẹ́ ẹnikẹ́ni jóná, òun yóò pàdánù, ṣùgbọ́n òun tìkára rẹ̀ ni a ó gbàlà, ṣùgbọ́n ìgbà ènìyàn la àárín iná kọjá.

16 3.16: 1Kọ 6.19; 2Kọ 6.16. Ṣé ̀yin tilẹ̀ mọ̀ tẹmpili Ọlọ́run ni ̀yin jẹ́? Àti pẹ̀pe ̀Ọlọ́run ń gbé inú yín? 17 ẹnikẹ́ni ba tẹmpili Ọlọ́run jẹ́, òun ni Ọlọ́run yóò parun; nítorí mímọ́ ni tẹmpili Ọlọ́run, èyí ̀yin jẹ́.

18 3.18: Isa 5.21; 1Kọ 8.2; Ga 6.3. ẹnikẹ́ni, ṣe tan ara rẹ̀ jẹ mọ́. ẹnikẹ́ni yín nínú ayé yìí ba òun gbọ́n, jẹ́ ó di òmùgọ̀ ó a le è gbọ́n. 19 3.19: Jb 5.13; 1Kọ 1.20.Nítorí ọgbọ́n ayé yìí jẹ́ òmùgọ̀ lọ́dọ̀ Ọlọ́run. Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ nínú Ìwé Mímọ́ , "Ẹni ti ó mu àwọn ọlọ́gbọ́n nínú àrékérekè wọn"; 20 3.20: Sm 94.11.lẹ́̀kan i, "Olúwa mọ̀ èrò inú àwọn ọlọ́gbọ́n asán wọn." 21 3.21: 1Kọ 4.6; Ro 8.32.Nítorí ẹnikẹ́ni ṣe ṣògo nínú ènìyàn. Nítorí yín ni ohun gbogbo. 22 3.22: 1Kọ 1.12; Ro 8.38.Ìbá ṣe Paulu, tàbí Apollo, tàbí Kefa, tàbí ayé tàbí ìyè, tàbí ikú, tàbí ohun ìsinsin yìí, tàbí ohun ìgbà ń bọ̀; tiyín ni gbogbo wọn. 23 ̀yin ni ti Kristi; Kristi ni ti Ọlọ́run.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-