Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Coríntios 5

yọ alágbèrè ọkùnrin kúrò

1 5.1: De 22.30; 27.20. Ìròyìn rẹ ń tàn kalẹ̀ ìwà àgbèrè wa láàrín yín, irú àgbèrè a tilẹ̀ gbúròó rẹ̀ láàrín àwọn aláìkọlà , ẹnìkan nínú yín ń fẹ́ ìyàwó baba rẹ̀. 2 ̀yin ń ṣe ìgbéraga! ̀yin kúkú káàánú a ẹni ó hu ìwà yìí kúrò láàrín yín? 3 5.3: Kl 2.5.Lóòtítọ́ èmi láàrín yín nípa ti ara, ṣùgbọ́n mo lọ́dọ̀ yín nínú ̀àti , orúkọ Olúwa Jesu Kristi, mo ṣe ìdájọ́ lórí irú ẹni bẹ́̀, ẹni mo láàrín yín. 4 5.4: 2Tẹ 3.6.orúkọ Jesu Kristi. Nígbà ̀yin péjọ, àti ̀mi si wa pẹ̀yin nínú ̀mi àti pẹ̀agbára Jesu Kristi Olúwa wa. 5 5.5: Mt 4.10; 1Kọ 1.3.fi irú ẹni bẹ́̀ Satani lọ́wọ́ fún ìparun ara, ó ba à le gba ̀rẹ ọjọ́ Olúwa wa Jesu Kristi.

6 5.6: Ga 5.9. Ìṣeféfé yín dára. ̀yin mọ̀ ìwúkàrà díẹ̀ gbogbo ìyẹ̀fun di wíwú? 7 Nítorí náà ìwúkàrà àtijọ́ kúrò nínú yín, ̀yin ó jẹ ìyẹ̀fun tuntun, gẹ́gẹ́ ̀yin jẹ àkàrà ti ìwúkàrà. Nítorí à ti fi ìrékọjá wa, àní Kristi ni a ti pa láti fi ṣe ẹbọ fún ̀ṣẹ̀ wa. 8 5.8: Ek 12.19; 13.7; De 16.3.Nítorí náà, jẹ́ á pa àjọ náà mọ́, í ṣe pẹ̀ìwúkàrà àtijọ́ bẹ́̀ ni í ṣe pẹ̀ìwúkàrà àrankàn àti ìwà búburú, ṣùgbọ́n pẹ̀àkàrà ìwúkàrà, àkàrà òtítọ́ àti òdodo.

9 5.9: 2Kọ 6.14. Nígbà mo kọ̀ṣáájú i yín, mo sọ fún yín , ṣe darapọ̀ pẹ̀àwọn alágbèrè ènìyàn. 10 5.10: 1Kọ 10.27.Nígbà mo sọ bẹ́̀ ń sọ̀rọ̀ nípa àwọn ayé yìí, wọ́n ń gbé ìgbé ayé wọn nínú ̀ṣẹ̀ àgbèrè, àti àwọn olójúkòkòrò ń rẹ́ ni jẹ, àwọn olè àti àwọn abọ̀rìṣà. Nítorí ó dájú ̀yin gbọdọ̀ kúrò nínú ayé yìí láti yẹra fún wọn. 11 5.11: 2Tẹ 3.6; 1Kọ 10.7,14,20-21.Ṣùgbọ́n nísinsin yìí mo kọ̀i yín , ẹnikẹ́ni a pe rẹ̀ ni arákùnrin jẹ́ àgbèrè, tàbí wọ̀bìà, tàbí abọ̀rìṣà, àti ẹlẹ́gàn, tàbí ̀mùtípara, tàbí alọ́nilọ́wọ́gbà. tilẹ̀ irú ẹni bẹ́̀ jẹun.

12 5.12: Mk 4.11. Nítorí èwo ni tèmi láti máa ṣe ìdájọ́ àwọn ń bẹ lóde? í ha ṣe àwọn ó nínú ni ̀yin ṣe ìdájọ́ wọn? 13 5.13: De 17.7; 1Kọ 5.2.Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ó ń bẹ lóde. "àwọn ènìyàn búburú náà kúrò láàrín yín."

Veja também