Publicidade

1 João 3

1 wo irú ìfẹ́ Baba fi fẹ́ wa, a fi ń ọmọ Ọlọ́run; bẹ́̀ ni a à jẹ́. Nítorí èyí ni ayé ṣe mọ̀ , nítorí mọ̀ ́n. 2 Olùfẹ́, ọmọ Ọlọ́run ni àwa ń ṣe nísinsin yìí, a ì i fihàn àwa ó ti : àwa mọ̀ , nígbà òun ba farahàn, àwa yóò dàbí rẹ̀; nítorí àwa yóò i, àní òun . 3 Olúkúlùkù ẹni ó ba ìrètí yìí nínú rẹ̀, ń wẹ ara rẹ̀ mọ́, àní òun ti mọ́.

4 Ẹnikẹ́ni ó ń dẹ́ṣẹ̀, ó ń òfin pẹ̀, nítorí ̀ṣẹ̀ ni rírú òfin. 5 ̀yin mọ̀ , òun farahàn láti mu ̀ṣẹ̀ kúrò; ̀ṣẹ̀ ṣí nínú rẹ̀. 6 Ẹnikẹ́ni ó ba ń gbé inú rẹ̀ í dẹ́ṣẹ̀; ẹnikẹ́ni ó ń dẹ́ṣẹ̀ i, bẹ́̀ ni mọ̀ ́n.

7 ̀yin ọmọ mi, ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni tàn yín, ẹni ó ń ṣe òdodo, ó jásí olódodo, gẹ́gẹ́ òun jẹ olódodo. 8 Ẹni ó ba ń dẹ́ṣẹ̀ èṣù ni; nítorí láti àtètèkọ́ṣe ni èṣù ti ń dẹ́ṣẹ̀. Nítorí èyí ni Ọmọ Ọlọ́run ṣe farahàn, ó pa iṣẹ́ èṣù run. 9 Ẹnikẹ́ni a ti ipa Ọlọ́run , í dẹ́ṣẹ̀; nítorí irú rẹ̀ ń gbé inú rẹ̀, dẹ́ṣẹ̀ nítorí a ti ti ipa Ọlọ́run i. 10 Nínú èyí ni àwọn ọmọ Ọlọ́run ń farahàn, àti àwọn ọmọ èṣù; ẹnikẹ́ni ba ń ṣe òdodo, àti ẹni fẹ́ràn arákùnrin rẹ̀ í ṣe ti Ọlọ́run.

Fẹ́ràn ọmọnìkejì rẹ

11 Nítorí èyí ni iṣẹ́ ̀yin gbọ́ ni àtètèkọ́ṣe, ki àwa fẹ́ràn ara wa. 12 í ṣe Kaini, í ṣe ẹni búburú, o pa arákùnrin rẹ̀. Nítorí kín ni ó ṣe pa á? Nítorí iṣẹ́ tirẹ̀ jẹ́ búburú ṣùgbọ́n arákùnrin rẹ̀ jẹ́ òdodo. 13 ẹnu ṣe yín, ̀yin ará mi, ayé kórìíra yín. 14 Àwa mọ̀ àwa rékọjá láti inú ikú sínú ìyè, nítorí àwa fẹ́ràn àwọn ará. Ẹni ba ni ìfẹ́, ó ń gbé inú ikú. 15 Ẹnikẹ́ni ó ba kórìíra arákùnrin rẹ̀ apànìyàn ni, ̀yin mọ́ apànìyàn ó ni ìyè àìnípẹ̀kun láti máa gbé inú rẹ̀.

16 Nípa èyí ni àwa mọ ìfẹ́ nítorí ó fi ̀rẹ̀ lélẹ̀ fún wa, ó yẹ àwa fi ̀wa lélẹ̀ fún àwọn ará. 17 Ṣùgbọ́n ẹni ó ni ohun ìní ayé, ó ri arákùnrin rẹ̀ ó ṣe aláìní, ó ìlẹ̀kùn ìyọ́rẹ̀ mọ́ ọn, báwo ni ìfẹ́ Ọlọ́run ṣe ń gbé inú rẹ̀? 18 ̀yin ọmọ mi, ṣe jẹ́ a fi ̀rọ̀ tàbí ahọ́n fẹ́ràn, ṣe ni ìṣe àti òtítọ́.

19 Àti nípa èyí ni àwa ó mọ̀ àwa jẹ́ ti òtítọ́, àti àwa ó fi ọkàn ara wa balẹ̀ níwájú rẹ̀. 20 Nínú ohunkóhun ọkàn wa ń wa lẹ́bi; nítorí Ọlọ́run tóbi ju ọkàn wa lọ, ó mọ ohun gbogbo. 21 Olùfẹ́, ọkàn wa wa lẹ́bi, ǹjẹ́ àwa ni ìgboyà níwájú Ọlọ́run? 22 Àti ohunkóhun àwa béèrè, ni àwa ń gbà lọ́dọ̀ rẹ̀, nítorí àwa ń pa òfin rẹ̀ mọ́, àwa ń ṣe àwọn nǹkan ó dára lójú rẹ̀. 23 Èyí ni òfin rẹ̀, àwa gba orúkọ Jesu Kristi Ọmọ rẹ̀ gbọ́, a fẹ́ràn ara gẹ́gẹ́ ó fi òfin fún wa. 24 Ẹni ó pa òfin rẹ̀ mọ́ ń gbé inú rẹ̀, àti òun nínú rẹ̀. Àti nípa èyí ni àwa mọ̀ ó ń gbé inú wa, nípa ̀ó fi fún wa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-