Publicidade

1 Pedro 2

1 Nítorí náà, fi àrankàn gbogbo sílẹ̀ ni apá kan, àti ̀tàn gbogbo, àti àgàbàgebè, àti ìlara, àti sísọ ̀rọ̀ búburú gbogbo. 2 ọmọ ọwọ́ tuntun, máa fẹ́ wàrà ti ̀, èyí lẹ́tàn, ̀yin máa tipasẹ̀ rẹ̀ dàgbà ìgbàlà, 3 nísinsin yìí ̀yin ti tọ́ rere ni Olúwa.

Àpáta iyè àti ènìyàn a yàn

4 Ẹni ̀yin ń tọ̀ bọ̀, bi òkúta ààyè náà, èyí ti a ti ọwọ́ ènìyàn kọ̀ sílẹ̀ nítòótọ́, ṣùgbọ́n lọ́dọ̀ Ọlọ́run, àṣàyàn òkúta iyebíye. 5 ̀yin pẹ̀, òkúta ààyè, ni a kọ́ ilé ̀, àlùfáà mímọ́, láti máa ẹbọ ̀, i ṣe ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ Ọlọ́run nípa Jesu Kristi. 6 Nítorí nínú Ìwé Mímọ́, ó pe:

"Kíyèsi i, mo fi pàtàkì òkúta igun ilé àṣàyàn,

iyebíye, lélẹ̀ ni Sioni:

ẹni ó gbà á gbọ́

ojú yóò í."

7 Báyìí fún ̀yin ti gbà á gbọ́, ó ṣe iyebíye; ṣùgbọ́n fún àwọn gbà á gbọ́,

"Òkúta àwọn ̀mọ̀kọ̀sílẹ̀,

òun ni ó di pàtàkì igun ilé,"

8 àti pẹ̀,

"Òkúta ìdìgbòlù,

àti àpáta ìkọ̀sẹ̀."

Nítorí wọ́n kọsẹ̀ nípa ṣíṣe àìgbọ́ràn ̀rọ̀ náà, sínú èyí a gbé yàn wọ́n pẹ̀.

9 Ṣùgbọ́n ̀yin ni ìran a yàn olú àlùfáà, Orílẹ̀-èdè mímọ́, ènìyàn ̀tọ̀ ki ̀yin fi ọláńlá ẹni ó yín jáde kúrò nínú òkùnkùn sínú ìmọ́lẹ̀ ìyanu rẹ̀ hàn. 10 ̀yin í ṣe ènìyàn nígbà kan , ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ̀yin ti di ènìyàn Ọlọ́run, ̀yin àánú gbà , ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ti àánú gbà.

Ìbọ̀wọ̀ fún àwọn òfin àti àwọn aláṣẹ

11 Olùfẹ́ ̀wọ́n, mo bẹ̀ yín, àjèjì àti àtìpó, láti fàsẹ́yìn kúrò nínú ìfẹ́kúfẹ̀́ ara, ń ba ọkàn jagun. 12 ìwà yín láàrín àwọn aláìkọlà dára; , wọ́n ti ń sọ̀rọ̀ yín olùṣe búburú, nípa iṣẹ́ rere yín wọn ó máa kíyèsi, wọ́n máa yin Ọlọ́run lógo lọ́jọ́ ti òun ba bẹ̀ .

13 máa tẹríba fún gbogbo ìlànà ènìyàn nítorí ti Olúwa, ìbá à ṣe fún ọba tàbí fún olórí. 14 Tàbí fún àwọn baálẹ̀, fún àwọn a rán láti ̀dọ̀ rẹ̀ láti gbẹ̀san lára àwọn ń ṣe búburú, àti fún ìyìn àwọn ń ṣe rere. 15 Ìfẹ́ Ọlọ́run ni èyí , rere í ṣe, dẹ́kun ̀rọ̀ àìmọ̀kan òmùgọ̀ ènìyàn. 16 máa gbé gẹ́gẹ́ ẹni òmìnira, ṣùgbọ́n ma ṣe lo òmìnira yín láti bo ibi mọ́lẹ̀; ṣùgbọ́n gbé gẹ́gẹ́ ìránṣẹ́ Ọlọ́run. 17 bọ̀wọ̀ fún gbogbo ènìyàn, fẹ́ àwọn ará, bẹ̀Ọlọ́run, bọ̀wọ̀ fún ọba.

18 ̀yin ọmọ ̀dọ̀, máa tẹríba fún àwọn ̀yín pẹ̀ìbẹ̀gbogbo, í ṣe fún àwọn ẹni rere àti oníwà tútù nìkan, ṣùgbọ́n fún àwọn òǹrorò pẹ̀. 19 Nítorí èyí ìgbóríyìn fún, ènìyàn fi ara da ìrora, ìjìyà lọ́àìtọ́, nítorí ọkàn rere Ọlọ́run. 20 Ṣùgbọ́n ògo kín ni ó jẹ́, nígbà ba ṣẹ̀ a yín, fi sùúrù gbà á? Ṣùgbọ́n nígbà ̀yin ń ṣe rere ń jìyà, fi sùúrù gbà á, ̀yín ọpẹ́ lọ́dọ̀ Ọlọ́run. 21 èyí ni a yín: nítorí Kristi pẹ̀jìyà fún un yin, ó fi àpẹẹrẹ sílẹ̀ fún un yín, ̀yin máa tọ ipasẹ̀ rẹ̀:

22 "Òun dẹ́ṣẹ̀ kankan,

bẹ́̀ ni, a ̀tàn kan lẹ́nu rẹ̀."

23 Ẹni, nígbà a kẹ́gàn rẹ̀, padà kẹ́gàn; nígbà ó jìyà halẹ̀; ṣùgbọ́n ó fi ̀ràn rẹ̀ ẹni ti ń ṣe ìdájọ́ òdodo lọ́wọ́. 24 Ẹni òun tìkára rẹ̀ fi ara rẹ̀ ru ̀ṣẹ̀ wa lórí igi àgbélébùú, àwa di òkú ̀ṣẹ̀, ki a di ààyè òdodo, nípa ìjìyà ẹni ó yín láradá. 25 Nítorí ̀yin ń ṣáko lọ àgùntàn, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ̀yin ti padà ̀dọ̀ olùṣọ́-àgùntàn àti bíṣọ́̀ọkàn yín.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-