Publicidade

1 Pedro 3

Àwọn aya àti àwọn ọkọ

1 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́, ̀yin aya, máa tẹríba fún àwọn ọkọ yín; , ẹnikẹ́ni ba tilẹ̀ ń ṣe àìgbọ́ràn ̀rọ̀ náà, a jèrè wọn láì sọ̀rọ̀ nípa ìwà àwọn aya wọn. 2 Nígbà wọ́n ń wo ìwà rere pẹ̀̀yín. 3 ̀ṣọ́ yín ṣe jẹ́ ̀ṣọ́ òde, irun dídì, àti wúrà lílò, tàbí ti aṣọ wíwọ̀; 4 ṣùgbọ́n ó jẹ́ ẹni ó fi ara sin ọkàn, nínú ̀ṣọ́ àìdíbàjẹ́ ti ̀ìrẹ̀lẹ̀ àti ̀tútù, èyí i ṣe iyebíye níwájú Ọlọ́run. 5 Nítorí báyìí ni àwọn obìnrin mímọ́ ìgbàanì pẹ̀, wọ́n gbẹ́kẹ̀Ọlọ́run, fi ṣe ara wọn lọ́ṣọ̀́, wọn a máa tẹríba fún àwọn ọkọ wọn. 6 Gẹ́gẹ́ Sara ti gbọ́ ti Abrahamu, ó ń é olúwa rẹ̀. Ọmọbìnrin ẹni ̀yin jẹ́, ̀yin ń ṣe rere, ohunkóhun dẹ́rùbà yín.

7 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ̀yin ọkọ, máa fi òye ba àwọn aya yín gbé, máa fi ọlá fún aya, bi ohun èlò ti lágbára, àti pẹ̀àjùmọ̀jogún oore-ọ̀fẹ́ ìyè; àdúrà yín á ìdènà.

Jíjìyà fún ṣíṣe iṣẹ́ rere

8 Lákòótan, gbogbo yín jẹ́ onínú kan, máa ara yín kẹ́dùn, ìfẹ́ ará, máa ṣe ìyọ́, ni ̀ìrẹ̀lẹ̀. 9 ṣe fi búburú san búburú, tàbí fi èébú san èébú: ṣùgbọ́n kàkà bẹ́̀, máa súre; nítorí èyí ni a yín , ̀yin jogún ìbùkún. 10 Nítorí,

"Ẹni yóò fẹ́ ìyè,

ti yóò ọjọ́ rere,

o pa ahọ́n rẹ̀ mọ́ kúrò nínú ibi,

àti ètè rẹ̀ mọ́ kúrò nínú sísọ ̀rọ̀ ̀tàn.

11 ó kúrò nínú ibi, ó máa ṣe rere;

ó máa àlàáfíà, ó máa lépa rẹ̀.

12 Nítorí ojú Olúwa ń bẹ lára àwọn olódodo,

etí rẹ̀ ṣí ̀bẹ̀ wọn,

ṣùgbọ́n ojú Olúwa korò àwọn ń ṣe búburú."

13 yóò ṣe yín ibi, ̀yin jẹ́ onítara ohun rere? 14 Ṣùgbọ́n ̀yin jìyà nítorí òdodo, a ti bùkún yín. "ṣe bẹ̀ìhàlẹ̀ wọn, ṣe kọminú." 15 Ṣùgbọ́n bọ̀wọ̀ fún Kristi Olúwa ọkàn yín: múra tan nígbà gbogbo láti olúkúlùkù lóhùn ń béèrè ìrètí o ń bẹ nínú yín, ṣùgbọ́n pẹ̀ọkàn tútù àti ìbẹ̀. 16 máa ni ̀ọkàn rere wọ́n ti ń sọ̀rọ̀ yín ibi, ojú ti àwọn ń kẹ́gàn ìwà rere yín nínú Kristi. 17 Nítorí ó sàn, ó jẹ́ ìfẹ́ Ọlọ́run, jìyà fún ṣíṣe rere ju fún ṣíṣe búburú lọ. 18 Nítorí Kristi pẹ̀jìyà lẹ́̀kan nítorí ̀ṣẹ̀ wa, olóòótọ́ fún àwọn aláìṣòótọ́, a wa ̀dọ̀ Ọlọ́run, ẹni a pa nínú ara, ṣùgbọ́n a sọ di ààyè nínú ̀. 19 Nínú èyí ó lọ pẹ̀ó wàásù fún àwọn ̀nínú túbú, 20 àwọn ó ṣe aláìgbọ́ràn nígbà kan, nígbà sùúrù Ọlọ́run dúró pẹ́ à kan ọjọ́ Noa, nígbà wọ́n fi kan ọkọ̀ nínú èyí a gba ọkàn díẹ̀ nípa omi, èyí ni ẹni mẹ́jọ. 21 Àpẹẹrẹ èyí ti ń gbà yín nísinsin yìí pẹ̀, àní ìtẹ̀bọmi, í ṣe wíwẹ́ èérí ti ara , ṣe ìdáhùn ̀ọkàn rere si Ọlọ́run, nípa àjíǹde Jesu Kristi. 22 Ẹni ó lọ ̀run, ó ń bẹ lọ́wọ́ ̀tún Ọlọ́run: pẹ̀àwọn angẹli, àwọn aláṣẹ, àti àwọn alágbára tẹríba lábẹ́ rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-