Publicidade

1 Timóteo 5

Ìmọ̀ràn nípa àwọn opó, àwọn alàgbà àti àwọn ẹrú

1 ṣe àgbàlagbà ọkùnrin , ṣùgbọ́n ó máa gbà á níyànjú i baba; àwọn ̀dọ́mọkùnrin arákùnrin. 2 Àwọn àgbàlagbà obìnrin ìyá; àwọn ̀dọ́mọbìnrin arábìnrin nínú ìwà mímọ́.

3 Bọ̀wọ̀ fún àwọn opó ti í ṣe opó nítòótọ́. 4 Ṣùgbọ́n opó kan ni ọmọ tàbí ọmọ ọmọ, jẹ́ wọn kọ́kọ́ kọ́ a ti ń ṣe ìtọ́ilé àwọn tìkára wọn, wọn san oore àwọn òbí wọn padà; nítorí èyí ni ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà níwájú Ọlọ́run. 5 Ǹjẹ́ ẹni ti í ṣe opó nítòótọ́, ti ó ṣe òun nìkan, a máa gbẹ́kẹ̀Ọlọ́run, a máa dúró nínú ̀bẹ̀ àti nínú àdúrà lọ́sàn àti lóru. 6 Ṣùgbọ́n ẹni ó fi ara rẹ fún ayé jíjẹ, ó nígbà ó láààyè. 7 Nǹkan wọ̀nyí ni wọn máa paláṣẹ, wọn láìlẹ́gàn. 8 Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni pèsè fún àwọn tirẹ̀, pàápàá fún àwọn ará ilé rẹ̀, ó ti sẹ́ ìgbàgbọ́, ó burú ju aláìgbàgbọ́ lọ.

9 Kọ orúkọ ẹni dín ni ọgọ́ta ọdún sílẹ̀ opó, lẹ́yìn ti ó ti jẹ́ aya ọkọ kan. 10 Ẹni ti a jẹ́rìí rẹ̀ fún iṣẹ́ rere; ẹni ti ó ti tọ́ ọmọ dàgbà, ti ó ń ṣe ìtọ́àlejò, ó ń wẹ ẹsẹ̀ àwọn ènìyàn mímọ́, ó ti ran àwọn olùpọ́njú lọ́wọ́, ó ń lépa iṣẹ́ rere gbogbo.

11 Ṣùgbọ́n ma ṣe kọ orúkọ àwọn opó dàgbà; nítorí nígbà tiwọn ti ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́ lòdì Kristi, wọn á tún fẹ́ láti gbéyàwó. 12 Wọn á di ẹlẹ́bi, nítorí wọn ti kọ ìgbàgbọ́ wọn ìṣáájú sílẹ̀. 13 Àti pẹ̀wọn ń kọ́ láti ṣe ̀lẹ, láti máa kiri láti ilédélé, í ṣe ̀lẹ nìkan, ṣùgbọ́n onísọkúsọ àti olófòófó pẹ̀, wọn a máa sọ ohun yẹ. 14 Nítorí náà, mo fẹ́ àwọn opó dàgbà máa gbéyàwó, wọn máa bímọ, wọn máa ṣe alábojútó ilé, wọn ṣe fi ààyè sílẹ̀ rárá fún ̀náà láti sọ̀rọ̀ ̀gàn. 15 Nítorí àwọn mìíràn ti yípadà kúrò ̀yìn Satani.

16 ọkùnrin tàbí obìnrin kan ó gbàgbọ́ àwọn opó, ó máa ràn wọ́n lọ́wọ́, a di ẹrù ìjọ, wọn máa ran àwọn ti í ṣe opó nítòótọ́ lọ́wọ́.

17 Àwọn alàgbà ti ó ṣe àkóso dáradára ni a yẹ ọlá ìlọ́po méjì, pẹ̀lúpẹ̀àwọn ti ó ṣe làálàá ni ̀rọ̀ àti ni kíkọ́ni. 18 Nítorí Ìwé Mímọ́ , "Ìwọ gbọdọ̀ di màlúù ti ń tẹ ọkà lẹ́nu," àti , "̀alágbàṣe tọ́ i." 19 ṣe gba ̀sùn alàgbà kan, ṣe láti ẹnu ẹlẹ́rìí méjì mẹ́ta. 20 àwọn ó ṣẹ̀ níwájú gbogbo ènìyàn, àwọn ìyókù pẹ̀á bẹ̀. 21 Mo pàṣẹ fún níwájú Ọlọ́run, àti Kristi Jesu, àti àwọn angẹli àyànfẹ́ ìwọ máa ṣàkíyèsí nǹkan wọ̀nyí, láìṣe ojúsàájú, láti fi ègbè ṣe ohunkóhun.

22 ṣe fi ìkánjú gbe ọwọ́ ẹnikẹ́ni, bẹ́̀ ni ó ṣe jẹ́ alábápín nínú ̀ṣẹ̀ àwọn ẹlòmíràn, pa ara rẹ mọ́ ìwà mímọ́.

23 Ma ṣe máa mu omi nìkan, ṣùgbọ́n máa lo wáìnì díẹ̀ nítorí inú rẹ, àti nítorí àìlera ìgbàkúgbà.

24 ̀ṣẹ̀ àwọn ẹlòmíràn a máa hàn gbangba, a máa lọ ṣáájú ìdájọ́; àwọn ẹlòmíràn pẹ̀a máa tẹ̀wọn. 25 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ pẹ̀ni iṣẹ́ rere wa máa ń hàn gbangba; wọn tilẹ̀ ì hàn, wọn fi ara sin títí.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-