Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Coríntios 2

1 Nítorí náà mo pinnu nínú ara , èmi yóò tún fi ìbànújẹ́ tọ̀ yin . 2 Nítorí èmi inú yín bàjẹ́, ǹjẹ́ ta ni ẹni ti ìbá inú dùn àkókò inú mi bàjẹ́ ṣe ẹni mo ti ba nínú jẹ́? 3 Èmi kọ̀mo kọ yín , nígbà mo de, èmi ṣe ni ìbànújẹ́ lọ́dọ̀ àwọn ti ìbá mi ayọ̀, nítorí mo ìgbẹ́kẹ̀nínú gbogbo yín, ̀yin yóò jẹ́ alábápín ayọ̀ mi. 4 Nítorí nínú ̀pọ̀lọpọ̀ wàhálà àti ìrora ọkàn ni mo ti fi ̀pọ̀lọpọ̀ omijé kọ̀yín; í ṣe nítorí a yín nínú jẹ́, ṣùgbọ́n ̀yin a mọ ìfẹ́ mo yín ṣe jinlẹ̀ .

Ìdáríjì fún ẹlẹ́ṣẹ̀

5 ẹnikẹ́ni fa ohun ìbànújẹ́ í ṣe èmi ni ó nínú jẹ́, ṣe ̀yin fúnra yín, níwọ̀n ìyówù ó jẹ́; n fẹ́ sọ ́ lọ́líle . 6 Ìyà náà ̀pọ̀lọpọ̀ ti fi jẹ́ irú ènìyàn bẹ́̀ fún un. 7 Kàkà bẹ́̀, ̀yin ìbá kúkú dáríjì í, ú nínú gbogbo ̀, ìbànújẹ́ á bo irú ènìyàn bẹ́̀ mọ́lẹ̀. 8 Nítorí náà mo bẹ̀ yín, fi ìdánilójú ìfẹ́ yín hàn irú ẹni náà. 9 Ìdí mo ṣe kọ̀ni èmi ba à ̀dìímú nípa ìgbọ́ràn yín nínú ohun gbogbo. 10 Ṣùgbọ́n ̀yin dáríjì ẹnikẹ́ni, èmi pẹ̀dáríjì í. Ohun èmi pẹ̀fi , nítorí tiyín mo fi níwájú Kristi. 11 Satani ba à rẹ́ wa jẹ. Nítorí àwa ṣe aláìmọ́ àrékérekè rẹ̀.

Ìránṣẹ́ májẹ̀tuntun

12 2.12: Ap 16.8. Ṣùgbọ́n nígbà ti mo Troasi láti wàásù ìyìnrere Kristi, mo i Olúwa ti ṣí ìlẹ̀kùn fún mi, 13 síbẹ̀ èmi àlàáfíà lọ́kàn mi, nítorí èmi Titu arákùnrin mi níbẹ̀. Nítorí ìdí èyí ni mo ṣe dágbére fún wọn, mo si rékọjá lọ Makedonia.

14 Ṣùgbọ́n ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run, ẹni ń yọ ayọ̀ ìṣẹ́gun lórí nígbà gbogbo nínú Kristi, a ń fi òórùn dídùn ìmọ̀ rẹ̀ hàn nípa wa níbi gbogbo. 15 Nítorí òórùn dídùn Kristi ni àwa jẹ́ fún Ọlọ́run, nínú àwọn a ń gbàlà àti nínú àwọn ó ń ṣègbé. 16 Fún àwọn kan, àwa jẹ́ òórùn ikú, àti fún àwọn mìíràn òórùn ìyè ìyè. Ta ni ó ha si tọ́ fún nǹkan wọ̀nyí? 17 Nítorí àwa dàbí àwọn ̀pọ̀lọpọ̀, ń fi ̀rọ̀ Ọlọ́run ṣòwò jẹun; ṣùgbọ́n nínú òtítọ́ inú àwa ń sọ̀rọ̀ níwájú Ọlọ́run nínú Kristi gẹ́gẹ́ àwọn a rán láti ̀dọ̀ Ọlọ́run .

Veja também