Publicidade

2 Coríntios 5

17 5.17: Ro 16.7; Ga 6.15.Nítorí náà ẹnìkan nínú Kristi, ó di ̀tuntun: ohun àtijọ́ ti kọjá lọ; kíyèsi i, ohun tuntun ti . 18 5.18: 1Kọ 11.12; Kl 1.20; Ro 5.10.Ohun gbogbo ti ̀dọ̀ Ọlọ́run , ẹni ó tipasẹ̀ Jesu Kristi wa làjà sọ́dọ̀ ara rẹ̀, ó ti fi iṣẹ́ ìránṣẹ́ ìlàjà fún wa. 19 Èyí ni , Ọlọ́run nínú Kristi, ó ń aráyé làjà sọ́dọ̀ ara rẹ̀, ka ìrékọjá wọn wọn lọ́rùn; ó ti fi ̀rọ̀ ìlàjà wa lọ́wọ́. 20 5.20: Ef 6.20.Nítorí náà àwa ni ikọ̀ fún Kristi, ẹni Ọlọ́run ń ti ̀dọ̀ wa ṣìpẹ̀ fún yín: àwa ń bẹ̀ yín ipò Kristi, "Ọlọ́run làjà." 21 5.21: Hb 4.15; 7.25; 1Pt 2.22; 1Jh 3.5; Ap 3.14.Nítorí ó fi í ṣe ̀ṣẹ̀ nítorí wa, ẹni mọ ̀ṣẹ̀kẹ́ṣẹ̀ , àwa di òdodo Ọlọ́run nínú rẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-