Publicidade

2 Coríntios 7

10 Nítorí ìbànújẹ́ ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run máa ṣiṣẹ́ ìrònúpìwàdà ìgbàlà í àbámọ̀ , ṣùgbọ́n ìbànújẹ́ ti ayé a máa ṣiṣẹ́ ikú. 11 Kíyèsi i, nítorí ohun kan náà yìí a yin banújẹ́ fún ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run, irú ìmúraṣíṣẹ́ ó jáde nínú yín, wíwẹ ara yín mọ́ ń kọ́, ìbànújẹ́ ń kọ́, ìpayà ń kọ́, ìfojúṣọ́ń kọ́, ìtara ń kọ́, ìjẹ́ni-níyà ń kọ́. Nínú ohun àmì kọ̀̀kan yìí ni ̀yin ti fi ara yín hàn aláìlẹ́bi nínú ̀ràn náà.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-