Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Coríntios 8

̀rọ̀ ìyànjú lórí ìfifúnni

1 Pẹ̀lúpẹ̀, ará, àwa ń sọ fún yín ti oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run a fífún àwọn ìjọ Makedonia. 2 ó ti jẹ́ a dán wọn nípa ìpọ́njú, ̀pọ̀lọpọ̀ ayọ̀ àti àìlódiwọ̀n àìní wọn ti kún àkúnwọ́sílẹ̀ nínú ̀rọ̀ ìlawọ́ wọn. 3 8.3: 1Kọ 16.2.Nítorí mo jẹ́rìí gẹ́gẹ́ agbára wọn, àní ju agbára wọn, wọ́n ṣe é láti ìfẹ́ inú ara wọn. 4 8.4: Ap 24.17; Ro 15.31.Wọ́n ń fi ̀bẹ̀ púpọ̀ rọ̀ ti ̀bùn àtinúwá yìí, láti ba à ìpín nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ fún àwọn ènìyàn mímọ́. 5 Àti èyí, í ṣe àwa , ṣùgbọ́n wọ́n tètè kọ́ fi àwọn fúnra wọn fún Olúwa, àti fún , nípa ìfẹ́ Ọlọ́run. 6 8.6: 2Kọ 8.16,23; 2.13.bẹ́̀ àwa fi gba Titu níyànjú , ó bẹ̀rẹ̀ náà, bẹ́̀ ni ó parí ̀bùn ̀fẹ́ yìí nínú yín pẹ̀. 7 Ṣùgbọ́n ̀yin ti pọ̀ lóhùn gbogbo, ìgbàgbọ́, àti ̀rọ̀ àti ìmọ̀, àti nínú iṣẹ́ ìyìnrere gbogbo, àti ìfẹ́ yín wa, i ̀yin pọ̀ i nínú ̀bùn ̀fẹ́ yìí pẹ̀.

8 í ṣe nípa àṣẹ ni mo fi ń sọ ́, ṣùgbọ́n a ìdí òtítọ́ ìfẹ́ yín pẹ̀, nípa iṣẹ́ ìyìnrere ẹlòmíràn. 9 8.9: 2Kọ 6.10.Nítorí ̀yin mọ oore-ọ̀fẹ́ Olúwa wa Jesu Kristi, òun ti jẹ́ ọlọ́rọ̀ ṣùgbọ́n nítorí yín ó di tálákà a sọ yín di ọlọ́rọ̀ nípa àìní rẹ̀.

10 8.10: 2Kọ 9.2; 1Kọ 16.2-3. Àti nínú èyí ni mo fi ìmọ̀ràn mi fún yín, nítorí èyí ṣe àǹfààní fún yín, ̀yin ó kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ níwọ̀n ọdún ó kọjá, í ṣe láti ṣe nǹkan, ṣùgbọ́n láti fẹ́ pẹ̀. 11 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, parí ṣíṣe iṣẹ́ náà pẹ̀; ó ba à ṣe , ìpinnu fún ṣíṣe ti , bẹ́̀ ni ìparí láti inú agbára yín. 12 Nítorí ìpinnu ṣáájú, ó jásí ìtẹ́wọ́gbà gẹ́gẹ́ ohun ènìyàn , í ṣe gẹ́gẹ́ ohun .

13 Nítorí èmi fẹ́ àwọn ẹlòmíràn ìrọ̀rùn, ó jẹ́ ìpọ́njú fún yín, ṣùgbọ́n nípa mímú dọ́gba. 14 àkókò yìí, àníṣẹ́yín ṣe déédé àìní wọn, àníṣẹ́tiwọn pẹ̀ba à ṣe déédé àìní yín, ìmúdọ́gba ba à . 15 8.15: Ek 16.18.Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ , "Ẹni ó púpọ̀ púpọ̀ , bẹ́̀ ni ẹni ó ìwọ̀nba kéré ."

A rán Titu Kọrinti

16 Ṣùgbọ́n ọpẹ́ fún Ọlọ́run ẹni ó fi ìtara àníyàn kan náà yìí ọkàn Titu fún yín. 17 Nítorí í ṣe òun gba ̀rọ̀ ìyànjú wa nìkan ni; ṣùgbọ́n òun ti ìtara púpọ̀, òun tìkára rẹ̀ tọ̀ yín , fúnra rẹ̀. 18 8.18: 2Kọ 12.18.Àwa ti rán arákùnrin náà pẹ̀rẹ̀, ìyìn ẹni ó nínú ìyìnrere yíká gbogbo ìjọ. 19 8.19: 1Kọ 16.3-4.í í ṣe bẹ́̀ nìkan, ṣùgbọ́n ẹni a yàn pẹ̀láti ̀dọ̀ ìjọ láti máa wa rìn kiri nínú ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ yìí, àwa ń ṣe ìránṣẹ́ rẹ̀ fún ògo Olúwa àti ìmúra ìtara wa. 20 Àwa ń yẹra fún èyí, ẹnikẹ́ni ba à wa ti ̀bùn àtinúwá yìí àwa pín. 21 Àwa ń gbèrò ohun rere, í ṣe níwájú Olúwa nìkan, ṣùgbọ́n níwájú ènìyàn pẹ̀.

22 Àwa ti rán arákùnrin wa pẹ̀wọn, ẹni àwa dájú nígbà púpọ̀ ó ìtara nínú ohun púpọ̀, ṣùgbọ́n ìsinsin yìí ni ìtara rẹ̀ túbọ̀ pọ̀ i nípa ìfọkàntán ńlá ó yín. 23 ẹnikẹ́ni béèrè ẹni Titu jẹ́, ẹlẹgbẹ́ àti olùbáṣiṣẹ́ mi ni, nítorí yín; tàbí ti àwọn arákùnrin wa ni ẹnikẹ́ni ń béèrè, ìránṣẹ́ ìjọ ni wọ́n jẹ́, àti ògo Kristi. 24 Nítorí náà fi ̀ìfẹ́ yín hàn wọ́n níwájú ìjọ, àti ìṣògo wa nítorí yín.

Veja também