Publicidade

Apocalipse 1

̀rọ̀ ìṣáájú

1 Ìfihàn ti Jesu Kristi, Ọlọ́run fi fún un, láti fihàn fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, ohun le ṣàìṣẹ lọ́́lọ́́; ó ránṣẹ́, ó fi í hàn láti ọwọ́ angẹli rẹ̀ fún Johanu, ìránṣẹ́ rẹ̀, 2 ẹni ó jẹ́rìí ohun gbogbo ó , èyí ì ni ̀rọ̀ Ọlọ́run, àti ̀ti Jesu Kristi. 3 Ẹni ìbùkún ni ẹni ń , àti àwọn ó ń gbọ́ ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ yìí, ó ń pa nǹkan wọ̀n-ọn-nì a kọ sínú rẹ̀ mọ́, nítorí ìgbà dẹ̀dẹ̀.

̀rọ̀ ìkíni àti ìyìn

4 Johanu,

àwọn ìjọ méje ń bẹ Asia:

Oore-ọ̀fẹ́ fún yín, àti àlàáfíà, láti ̀dọ̀ ẹni ó ń bẹ, ó ti , ó ń bọ̀ ; àti láti ̀dọ̀ àwọn ̀méje ń bẹ níwájú ìtẹ́ rẹ̀; 5 àti láti ̀dọ̀ Jesu Kristi, ẹlẹ́rìí olóòtítọ́, àkọ́nínú àwọn òkú, àti aláṣẹ àwọn ọba ayé.

Ẹni ó fẹ́ wa, ẹni ó gbà kúrò lọ́wọ́ ̀ṣẹ̀ wa nípa ̀jẹ̀ rẹ̀, 6 ó ti fi jẹ ọba àti àlùfáà láti sin Ọlọ́run àti Baba rẹ; tirẹ̀ ni ògo àti ìjọba láé àti láéláé. Àmín.

7 "Kíyèsi i, o ń bọ̀ nínú àwọsánmọ̀,

gbogbo ojú ni yóò i,

àti àwọn ó gún un ̀kọ̀ pẹ̀";

àti gbogbo orílẹ̀-èdè ayé ni

"yóò máa pohùnréré ẹkún nítorí rẹ̀."

Bẹ́̀ náà ni! Àmín.

8 "Èmi ni Alfa àti Omega," ni Olúwa Ọlọ́run , "ẹni ó ń bẹ, ó ti , ó ń bọ̀ , alágbára."

̀kan gẹ́gẹ́ Ọmọ Ènìyàn

9 Èmi, Johanu, arákùnrin yín àti alábápín pẹ̀yín nínú wàhálà àti ìjọba àti sùúrù ń bẹ nínú Jesu, erékúṣù a ń Patmo, nítorí ̀rọ̀ Ọlọ́run, àti nítorí ̀Jesu Kristi. 10 Mo nínú ̀ọjọ́ Olúwa, mo gbọ́ ohùn ńlá kan lẹ́yìn mi, ìró ìpè, 11 Ó ń , "Kọ́ ìwé rẹ̀, ohun ìwọ , ó fi ránṣẹ́ àwọn ìjọ méje; Efesu, àti Smirna, àti Pargamu, àti Tiatira, àti Sardi, àti Filadelfia, àti Laodikea."

12 Mo padà láti wo ohùn ń mi sọ̀rọ̀. Nígbà mo yípadà, mo ̀fìtílà wúrà méje, 13 àti láàrín àwọn ̀fìtílà náà, ẹnìkan ó dàbí "ọmọ ènìyàn," a wọ̀ aṣọ ó kanlẹ̀ ẹsẹ̀, a fi àmùrè wúrà ̀gbẹ́. 14 Orí rẹ̀ àti irun rẹ̀ funfun ̀gbọ̀n òwú, ó funfun yìnyín; ojú rẹ̀ dàbí, ọwọ́ iná. 15 Ẹsẹ̀ rẹ̀ dàbí idẹ dáradára, ẹni a á nínú ìléru; ohùn rẹ̀ dàbí ìró omi púpọ̀. 16 Ó ìràwọ̀ méje ọwọ́ ̀tún rẹ̀; àti láti ẹnu rẹ̀ ni idà olójú méjì mímú ti jáde. Ojú rẹ̀ dàbí oòrùn ó ń fi agbára rẹ̀ hàn.

17 Nígbà mo i, mo wólẹ̀ ẹsẹ̀ rẹ̀ ẹni ó . Ó fi ọwọ́ ̀tún rẹ̀ mi, ó ń fún mi , "ṣe bẹ̀. Èmi ni ẹni ìṣáájú àti ẹni ìkẹyìn. 18 Èmi ni ẹni ó ń bẹ láààyè, ó ti ; kíyèsi i, èmi ń bẹ láààyè i títí láé! Mo kọ́kọ́rọ́ ikú àti ti ipò òkú lọ́wọ́.

19 "Kọ̀nítorí náà ohun ìwọ ti , àti ti ohun ń bẹ, àti ti ohun yóò lẹ́yìn èyí; 20 ohun ìjìnlẹ̀ ìràwọ̀ méje náà ìwọ ọwọ́ ̀tún mi, àti ̀wúrà fìtílà méje náà. Ìràwọ̀ méje ni àwọn angẹli ìjọ méje náà: àti ̀fìtílà méje náà àwọn ìjọ méje.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-