Publicidade

Apocalipse 19

Haleluya

1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí mo gbọ́ ohùn ńlá ̀run ẹni ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, ń :

"Haleluya!

Ti Olúwa Ọlọ́run wa ni ìgbàlà, àti ọlá àti agbára,

2 nítorí òtítọ́ àti òdodo ni ìdájọ́ rẹ̀.

Nítorí o ti ṣe ìdájọ́ àgbèrè ńlá a ,

o fi àgbèrè rẹ̀ ba ilẹ̀ ayé jẹ́, ó ti gbẹ̀san ̀jẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ̀ náà."

3 Àti lẹ́̀kejì wọ́n :

"Haleluya!

Èéfín rẹ̀ gòkè lọ láé àti láéláé."

4 Àwọn àgbà mẹ́rìnlélógún , àti àwọn ̀alààyè mẹ́rin wólẹ̀, wọ́n foríbalẹ̀ fún Ọlọ́run ó jókòó lórí ìtẹ́, :

"Àmín, Haleluya!"

5 Ohùn kan ti ibi ìtẹ́ náà jáde , :

"máa yin Ọlọ́run wa,

̀yin ìránṣẹ́ rẹ̀ gbogbo,

̀yin ó bẹ̀rẹ̀,

àti èwe àti àgbà!"

6 Mo gbọ́ ẹni ohùn ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, àti ìró omi púpọ̀, àti ìró àrá ńlá ńlá, ń :

"Haleluya!

Nítorí Olúwa Ọlọ́run wa, Olódùmarè ń jẹ ọba.

7 jẹ́ a yọ̀, inú wa ó dùn gidigidi,

a fi ògo fún un.

Nítorí ìgbéyàwó ̀dọ́-Àgùntàn ,

aya rẹ̀ ti múra tán.

8 Òun ni a fi fún ó wọ aṣọ ̀gbọ̀

wíwẹ́ ó funfun gbòò."

(Nítorí aṣọ ̀gbọ̀ dúró fún iṣẹ́ òdodo àwọn ènìyàn mímọ́.)

9 Ó fún mi , "Kọ̀rẹ̀, Ìbùkún ni fún àwọn a àsè alẹ́ ìgbéyàwó ̀dọ́-àgùntàn.’ " Ó fún mi , "Ìwọ̀nyí ni ̀rọ̀ òtítọ́ Ọlọ́run."

10 Mo wólẹ̀ ẹsẹ̀ rẹ̀ láti foríbalẹ̀ fún un. Ó fún mi , "ó, ṣe bẹ́̀: ìránṣẹ́ ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ ni èmi, àti ti àwọn arákùnrin rẹ̀ wọ́n di ̀Jesu . Foríbalẹ̀ fún Ọlọ́run: nítorí ̀Jesu ni ìsọtẹ́lẹ̀."

Ẹni gun ẹṣin funfun

11 Mo ̀run ṣí sílẹ̀, ó, ẹṣin funfun kan; ẹni ó jókòó lórí rẹ̀ ni à ń Olódodo àti Olóòtítọ́, nínú òdodo ni ó ń ṣe ìdájọ́, ó ń jagun. 12 Ojú rẹ̀ dàbí ̀wọ́-iná, àti orí rẹ̀ ni adé púpọ̀ ; ó orúkọ kan a kọ, ẹnikẹ́ni mọ́, ṣe òun tìkára rẹ̀. 13 A wọ̀ ́ aṣọ a tẹ̀ bọ inú ̀jẹ̀, a ń pe orúkọ rẹ̀ ̀rọ̀ Ọlọ́run. 14 Àwọn ogun ń bẹ ̀run a wọ̀ aṣọ ̀gbọ̀ wíwẹ́, funfun àti mímọ́, ń tọ̀ ́ lẹ́yìn lórí ẹṣin funfun. 15 Àti láti ẹnu rẹ̀ ni idà mímú ti ń jáde lọ, ó máa fi àwọn orílẹ̀-èdè: "Òun ó máa fi ̀irin ṣe àkóso wọn." Ó ń tẹ ìfúntí àti ìbínú Ọlọ́run Olódùmarè. 16 Ó lára aṣọ rẹ̀ àti ni ìtàn rẹ̀ orúkọ kan a kọ:

Ọba àwọn ọba àti Olúwa àwọn olúwa.

17 Mo angẹli kan dúró nínú oòrùn; ó fi ohùn rara kígbe, ó ń fún gbogbo àwọn ẹyẹ ń agbede-méjì ̀run , "ara yín jọ pọ̀ àsè ńlá Ọlọ́run; 18 ̀yin ó jẹ ẹran-ara àwọn ọba, àti ẹran-ara àwọn olórí ogun àti ẹran-ara àwọn ènìyàn alágbára, àti ẹran àwọn ẹṣin, àti ti àwọn ó jókòó lórí wọn, àti ẹran-ara ènìyàn gbogbo, àti ti òmìnira, àti ti ẹrú, àti ti èwe àti ti àgbà."

19 Mo ẹranko náà àti àwọn ọba ayé, àti àwọn ogun wọn a gbá jọ láti ẹni ó jókòó lórí ẹṣin náà àti ogun rẹ̀ jagun. 20 A ẹranko náà, àti wòlíì èké pẹ̀rẹ̀, ó ti ń ṣe iṣẹ́ ìyanu níwájú rẹ̀, èyí ó fi ń tan àwọn ó gba àmì ẹranko náà àti àwọn ń foríbalẹ̀ fún àwòrán rẹ̀ jẹ. Àwọn méjèèjì yìí ni a sọ láààyè sínú adágún iná ń fi sulfuru . 21 Àwọn ìyókù ni a fi idà ẹni ó jókòó lórí ẹṣin náà pa, àní idà ó ti ẹnu rẹ̀ jáde, gbogbo àwọn ẹyẹ ti ipa ẹran-ara wọn .

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-