Publicidade

Apocalipse 2

ìjọ Efesu

1 "angẹli ìjọ Efesu kọ̀:

Nǹkan wọ̀nyí ẹni ó ìràwọ̀ méje náà ni ọwọ́ ̀tún rẹ̀ , ẹni ń rìn àárín ̀wúrà fìtílà méje.

2 Èmi mọ iṣẹ́ rẹ, àti làálàá rẹ, àti ìfaradà rẹ, àti ara rẹ ti gba àwọn ẹni búburú, àti ìwọ ti dán àwọn ń pe ara wọn aposteli, wọ́n í í ṣe bẹ́̀ wo, ìwọ èké ni wọ́n, 3 ìwọ faradà ìyà, àti nítorí orúkọ mi ó rọ́, àárẹ̀ .

4 Síbẹ̀ èyí ni mo , , ìwọ ti fi ìfẹ́ ìṣáájú rẹ sílẹ̀. 5 Rántí ibi ìwọ ti gbé ṣubú! Ronúpìwàdà, ó ṣe iṣẹ́ ìṣáájú; ṣe bẹ́̀, èmi ó tọ̀ ́ , èmi ó ṣí ̀fìtílà rẹ̀ kúrò ipò rẹ̀, ṣe ìwọ ronúpìwàdà. 6 Ṣùgbọ́n èyí ni ìwọ , ìwọ kórìíra ìṣe àwọn Nikolatani, èyí èmi pẹ̀kórìíra.

7 Ẹni ó etí ó gbọ́ ohun ̀ń sọ fún àwọn ìjọ. Ẹni ó ṣẹ́gun ni èmi yóò fi èso igi ìyè fún jẹ, ń bẹ láàrín Paradise Ọlọ́run.

Ìjọ Smirna

8 "Àti angẹli ìjọ Smirna kọ̀.

Nǹkan wọ̀nyí ni ẹni í ṣe ẹni ìṣáájú àti ẹni ìkẹyìn , ẹni ó ti , ó tún .

9 Èmi mọ iṣẹ́ rẹ, àti ìpọ́njú, àti àìní rẹṣùgbọ́n ọlọ́rọ̀ ni ́, èmi mọ ̀rọ̀-òdì àwọn ń , Júù ni àwọn tìkára wọn, wọn í ṣe bẹ́̀, ṣùgbọ́n wọ́n jẹ́ Sinagọgu ti Satani. 10 ṣe bẹ̀ohunkóhun ìwọ ń bọ jìyà rẹ̀. Kíyèsi i, èṣù yóò gbé nínú yín sínú túbú, a dán yin ; ̀yin ó ìpọ́njú ọjọ́ mẹ́wàá, ìwọ ṣa ṣe olóòtítọ́ ojú ikú, èmi ó fi adé ìyè fún .

11 Ẹni ó etí ó gbọ́ ohun ̀ń sọ fún àwọn ìjọ. Ẹni ó ṣẹ́gun yóò fi ara pa nínú ikú kejì.

ìjọ Pargamu

12 "Àti angẹli ìjọ ni Pargamu kọ̀.

̀rọ̀ wọ̀nyí ni ẹni ó idà mímú olójú méjì.

13 Èmí mọ̀ ibi ìwọ ń gbé, àní ibi ìtẹ́ Satani . Síbẹ̀ ìwọ di orúkọ mi ṣinṣin. Ìwọ sẹ́ ìgbàgbọ́ nínú mi, pàápàá jùlọ ni ọjọ́ Antipa ẹlẹ́rìí mi, olóòtítọ́ ènìyàn, ẹni wọn pa láàrín yín, níbi Satani ń gbé.

14 Ṣùgbọ́n mo ni nǹkan díẹ̀ ; nítorí ìwọ àwọn kan ó di ̀kọ́ Balaamu síbẹ̀, ẹni ó kọ́ Balaki láti ohun ìkọ̀sẹ̀ síwájú àwọn ọmọ Israẹli, láti máa jẹ ohun a pa ẹbọ òrìṣà, àti láti máa ṣe àgbèrè. 15 Bẹ́̀ ni ìwọ àwọn ó gbá ̀kọ́ àwọn Nikolatani pẹ̀, ohun mo kórìíra. 16 Nítorí náà, ronúpìwàdà; ṣe bẹ́̀, èmi ó tọ̀ ́ nísinsin yìí, èmí o fi idà ẹnu mi wọn .

17 Ẹni ó létí, ó gbọ́ ohun ̀ń sọ fún àwọn ìjọ. Ẹni o ṣẹ́gun ni èmi o fi manna ó pamọ́ fún, èmi ó fún un ni òkúta funfun kan, àti sára òkúta náà ni a kọ orúkọ tuntun kan, ẹnìkan mọ̀ ṣe ẹni ó gbà á.

ìjọ ni Tiatira

18 "Àti angẹli ìjọ Tiatira kọ̀.

Nǹkan wọ̀nyí ni Ọmọ Ọlọ́run , ẹni ojú rẹ̀ dàbí ̀wọ́-iná, ẹsẹ̀ rẹ̀ dàbí idẹ dáradára.

19 Èmi mọ̀ iṣẹ́, ìfẹ́, àti ìgbàgbọ́ àti ìsìn àti sùúrù rẹ̀; àti iṣẹ́ rẹ̀ ìkẹyìn ju ìṣáájú lọ.

20 Ṣùgbọ́n èyí ni mo , nítorí ìwọ fi ààyè sílẹ̀ fún obìnrin Jesebeli ó ń pe ara rẹ̀ wòlíì. Nípasẹ̀ ̀kọ́ rẹ̀, ó ń kọ́ àwọn ìránṣẹ́ mi, ó ń tàn wọ́n láti máa ṣe àgbèrè, àti láti máa jẹ ohun a pa ẹbọ òrìṣà. 21 Èmi fi àkókò fún un, láti ronúpìwàdà; ṣùgbọ́n òun fẹ́ ronúpìwàdà àgbèrè rẹ̀. 22 Nítorí náà, èmi ó gbé e sọ orí àkéte ìpọ́njú, àti àwọn ń a ṣe panṣágà ni èmi ó fi sínú ìpọ́njú ńlá, ṣe wọ́n ronúpìwàdà iṣẹ́ wọn. 23 Èmi o pa àwọn ọmọ rẹ̀ run; gbogbo ìjọ ni yóò mọ̀ , èmi ni ẹni ń wádìí inú àti ọkàn, èmi ó fi fún olúkúlùkù yín gẹ́gẹ́ iṣẹ́ rẹ̀.

24 Ṣùgbọ́n ̀yin ni ń sọ fún, ̀yin ìyókù ń bẹ Tiatira, gbogbo ̀yin ni ̀kọ́ yìí, ti ì ì mọ̀ ohun wọn ni ohun ìjìnlẹ̀ Satani, èmi di ẹrù mìíràn yín, 25 ṣùgbọ́n èyí ̀yin , di ṣinṣin títí èmi ó fi .

26 Ẹni ó ṣẹ́gun, àti ó ṣe ìfẹ́ mi títí òpin, èmi ó fún un láṣẹ lórí àwọn orílẹ̀-èdè: 27 Òun ó máa fi ̀irin ṣe àkóso wọn; gẹ́gẹ́ a ti ń fọ́ ohun èlò amọ̀kòkò ni a ó fọ́ wọn túútúú,gẹ́gẹ́ èmi pẹ̀gbà àṣẹ láti ̀dọ̀ Baba mi. 28 Èmi yóò fi ìràwọ̀ òwúrọ̀ fún un. 29 Ẹni ó létí, ó gbọ́ ohun ̀ń sọ fún àwọn ìjọ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-