Pular para o conteúdo
Publicidade

Ìfihàn 20

Àwọn òkú gba ìdájọ́

11 20.11-12: Da 7.9-10. Mo ìtẹ́ funfun ńlá kan, àti ẹni ó jókòó lórí rẹ̀, níwájú ẹni ayé àti ̀run lọ; a ààyè fún wọn mọ́. 12 Mo àwọn òkú, àti èwe àti àgbà, wọn dúró níwájú ìtẹ́; a ṣí àwọn ìwé sílẹ̀; a ṣí àwọn ìwé mìíràn kan sílẹ̀ í ṣe ìwé ìyè: a ṣe ìdájọ́ fún àwọn òkú láti inú ohun a ti kọ sínú àwọn ìwé náà, gẹ́gẹ́ iṣẹ́ wọn. 13 Òkun jọ̀wọ́ àwọn òkú ń bẹ nínú rẹ̀ lọ́wọ́; àti òkú àti ipò òkú jọ̀wọ́ òkú ó nínú wọn pẹ̀: a ṣe ìdájọ́ wọn, olúkúlùkù gẹ́gẹ́ iṣẹ́ wọn. 14 Àti ikú àti ipò òkú ni a sọ sínú adágún iná. Èyí ni ikú kejì. 15 20.15: If 3.5.a ẹnikẹ́ni a kọ orúkọ rẹ̀ sínú ìwé ìyè, a ó sọ ́ sínú adágún iná.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também