Publicidade

Apocalipse 21

Jerusalẹmu tuntun

1 Mo ̀run tuntun kan àti ayé tuntun kan, nítorí ̀run ti ìṣáájú àti ayé ìṣáájú ti kọjá lọ; Òkun ṣí mọ́. 2 Mo ìlú mímọ́, Jerusalẹmu tuntun ń ti ̀run sọ̀kalẹ̀ láti ̀dọ̀ Ọlọ́run, a ti múra sílẹ̀ ìyàwó a ṣe lọ́ṣọ̀́ fún ọkọ rẹ̀. 3 Mo gbọ́ ohùn ńlá kan láti orí ìtẹ́ náà , ń , "Kíyèsi i, àgọ́ Ọlọ́run pẹ̀àwọn ènìyàn, òun ó máa wọn gbé, wọn ó máa jẹ́ ènìyàn rẹ̀, àti Ọlọ́run tìkára rẹ̀ yóò pẹ̀wọn, yóò máa jẹ́ Ọlọ́run wọn. 4 Ọlọ́run yóò nu omijé gbogbo kúrò ni ojú wọn; yóò ṣí ikú mọ́, tàbí ̀fọ̀, tàbí ẹkún, bẹ́̀ ni yóò ìrora mọ́, nítorí ohun àtijọ́ kọjá lọ."

5 Ẹni ó jókòó lórí ìtẹ́ náà, , "Kíyèsi i, mo sọ ohun gbogbo di ̀tun!" Ó fún mi , "Kọ̀rẹ̀, nítorí ̀rọ̀ wọ̀nyí òdodo àti òtítọ́ ni wọ́n."

6 Ó fún mi , "Ó parí. Èmi ni Alfa àti Omega, ìpilẹ̀ṣẹ̀ àti òpin. Èmi ó fi omi fún ẹni òùngbẹ ń gbẹ láti inú orísun omi ìyè lọ́fẹ̀́. 7 Ẹni ó ba ṣẹ́gun ni yóò jogún nǹkan wọ̀nyí; èmi ó máa jẹ́ Ọlọ́run rẹ̀, òun ó máa jẹ ọmọ mi. 8 Ṣùgbọ́n àwọn ojo, àti aláìgbàgbọ́, àti ẹni ìríra, àti apànìyàn, àti àgbèrè, àti oṣó, àti abọ̀rìṣà, àti àwọn èké gbogbo, ni yóò ni ipa tiwọn nínú adágún ń fi iná àti sulfuru : èyí i ṣe ikú kejì."

9 ̀kan nínú àwọn angẹli méje, wọ́n ni ago méje, ó kún fún ìyọnu méje ìkẹyìn , ó ba mi sọ̀rọ̀ , "níhìn-ín, èmi ó fi ìyàwó, aya ̀dọ́-àgùntàn hàn ́." 10 Ó mu mi lọ nínú ̀si òkè ńlá kan o ga, ó fi ìlú náà hàn mi, Jerusalẹmu mímọ́, ń ti ̀run sọ̀kalẹ̀ láti ̀dọ̀ Ọlọ́run, 11 ó ògo Ọlọ́run, ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ dàbí òkúta iyebíye gidigidi, àní òkúta jasperi, ó mọ́ kirisitali; 12 Ó odi ńlá àti gíga, ó ni ẹnu ibodè méjìlá, àti àwọn ẹnu ibodè náà angẹli méjìlá àti orúkọ a kọ sára wọn i ṣe orúkọ àwọn ̀méjìlá àwọn ọmọ Israẹli. 13 ìhà ìlà-oòrùn ẹnu ibodè mẹ́ta; ìhà àríwá ẹnu ibodè mẹ́ta; ìhà gúúsù ẹnu ibodè mẹ́ta; àti ìhà ìwọ̀-oòrùn ẹnu ibodè mẹ́ta. 14 Odi ìlú náà ni ìpìlẹ̀ méjìlá, àti lórí wọn orúkọ àwọn Aposteli méjìlá ̀dọ́-Àgùntàn.

15 Ẹni o ń mi sọ̀rọ̀ ̀pá-ìwọ̀n wúrà kan láti fi wọn ìlú náà àti àwọn ẹnu ibodè rẹ̀, àti odi rẹ̀. 16 Ìlú náà ibú mẹ́rin lọ́gbọọgba, gígùn rẹ̀ àti ìbú rẹ̀ dọ́gba: ó fi ̀pá-ìwọ̀n náà wọn ìlú náà , ó jẹ ẹgbàá mẹ́(12,000) ibùsọ̀ gígùn rẹ̀ àti ìbú rẹ̀, àti gíga rẹ̀ dọ́gba. 17 Ó wọn odi rẹ̀ ó jẹ́ ogóje ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rin (144), gẹ́gẹ́ òsùwọ̀n ènìyàn, bẹ́̀ ni angẹli náà. 18 A fi jasperi mọ odi ìlú náà. Ìlú náà jẹ́ kìkì wúrà, ó dàbí dígí o mọ́ kedere. 19 A fi onírúurú òkúta iyebíye ṣe ìpìlẹ̀ ògiri ìlú náà lọ́ṣọ̀́. Ìpìlẹ̀ èkínní jẹ́ jasperi; èkejì, safiru; ̀kẹta, kalkedoni; ̀kẹrin, emeradi; 20 ̀karùnún, sardoniki; ̀kẹfà, kaneliani; èkeje, krisoliti; ̀kẹjọ, berili; ̀kẹsànán, topasi; ̀kẹwàá, krisoprasu; ̀kọkànlá, jakiniti; èkejìlá, ametisiti. 21 Ẹnu ibodè méjèèjìlá jẹ́ perli méjìlá: olúkúlùkù ẹnu ibodè jẹ́ peali kan; ̀ìgboro ìlú náà jẹ́ kìkì wúrà, ó dàbí dígí dídán.

22 Èmi ri tẹmpili nínú rẹ̀, nítorí Olúwa Ọlọ́run Olódùmarè ni tẹmpili rẹ̀, àti ̀dọ́-àgùntàn. 23 Ìlú náà oòrùn, tàbí òṣùpá, láti máa tan ìmọ́lẹ̀ i, nítorí ògo Ọlọ́run ni ó ń tàn ìmọ́lẹ̀ i, ̀dọ́-àgùntàn ni fìtílà rẹ̀. 24 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò máa rìn nípa ìmọ́lẹ̀ rẹ̀, àwọn ọba ayé ń ògo wọn sínú rẹ̀. 25 A yóò ṣé àwọn ẹnu ibodè rẹ̀ rárá ̀sán: nítorí ki yóò si òru níbẹ̀. 26 Wọ́n ó máa ògo àti ọlá àwọn orílẹ̀-èdè sínú rẹ̀. 27 Ohun aláìmọ́ kan ki yóò wọ inú rẹ̀ rárá, tàbí ohun ń ṣiṣẹ́ ìríra àti èké; ṣe àwọn a kọ sínú ìwé ìyè ̀dọ́-àgùntàn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-