Pular para o conteúdo
Publicidade

Ìfihàn 21

10 21.10: El 40.2.Ó mu mi lọ nínú ̀si òkè ńlá kan o ga, ó fi ìlú náà hàn mi, Jerusalẹmu mímọ́, ń ti ̀run sọ̀kalẹ̀ láti ̀dọ̀ Ọlọ́run, 11 ó ògo Ọlọ́run, ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ dàbí òkúta iyebíye gidigidi, àní òkúta jasperi, ó mọ́ kirisitali; 12 21.12: El 48.30-35; Ek 28.21.Ó odi ńlá àti gíga, ó ni ẹnu ibodè méjìlá, àti àwọn ẹnu ibodè náà angẹli méjìlá àti orúkọ a kọ sára wọn i ṣe orúkọ àwọn ̀méjìlá àwọn ọmọ Israẹli. 13 ìhà ìlà-oòrùn ẹnu ibodè mẹ́ta; ìhà àríwá ẹnu ibodè mẹ́ta; ìhà gúúsù ẹnu ibodè mẹ́ta; àti ìhà ìwọ̀-oòrùn ẹnu ibodè mẹ́ta. 14 Odi ìlú náà ni ìpìlẹ̀ méjìlá, àti lórí wọn orúkọ àwọn Aposteli méjìlá ̀dọ́-Àgùntàn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também