Pular para o conteúdo
Publicidade

Atos 15

Àjọ ìgbìmọ̀ Jerusalẹmu

1 15.1-30: Ga 2.1-10. Àwọn ọkùnrin kan Judea sọ̀kalẹ̀ , wọ́n kọ́ àwọn arákùnrin , "ṣe a kọ yín ni ilà ìṣe Mose, ̀yin yóò ." 2 Nígbà Paulu àti Barnaba ni ìyapa àti ìyàn jíjà mọ níwọ̀n pẹ̀ara wọn, wọ́n yan Paulu àti Barnaba àti àwọn mìíràn nínú aposteli wọn gòkè lọ Jerusalẹmu, sọ́dọ̀ àwọn alàgbà nítorí ̀ràn yìí. 3 Nítorí náà, ìjọ ti rán wọn jáde lọ ̀wọn, wọn la Fonisia àti Samaria kọjá, wọ́n ń ròyìn ìyípadà àwọn aláìkọlà, wọ́n fi ayọ̀ ńlá fún gbogbo àwọn arákùnrin. 4 Nígbà wọn Jerusalẹmu, ìjọ àti àwọn aposteli àti àwọn alàgbà tẹ́wọ́gbà wọ́n, wọ́n ròyìn ohun gbogbo Ọlọ́run ti ṣe nípasẹ̀ wọn.

5 Ṣùgbọ́n àwọn kan nínú ̀àwọn Farisi wọ́n gbàgbọ́ dìde, wọ́n ń , "A láti kọ wọ́n ilà, àti láti pàṣẹ fún wọn wọn máa pa òfin Mose mọ́."

6 Àwọn aposteli àti àwọn alàgbà péjọ láti si ̀ràn yìí. 7 Nígbà iyàn di púpọ̀, Peteru dìde, ó fún wọn , "Ará, ̀yin mọ̀ , láti ìbẹ̀rẹ̀ ni Ọlọ́run ti yàn nínú yín , àwọn aláìkọlà gbọ́ ̀rọ̀ ìyìnrere láti ẹnu mi, wọn gbàgbọ́. 8 Ọlọ́run, ó jẹ́ olùmọ̀-ọkàn, jẹ́ wọn lẹ́rìí, ó fún wọn ni ̀Mímọ́, gẹ́gẹ́ àwa. 9 fi ìyàtọ̀ àárín àwa àti àwọn, ó ń fi ìgbàgbọ́ wẹ̀ wọ́n lọ́kàn mọ́. 10 Ǹjẹ́ nítorí náà èéṣe ̀yin o fi dán Ọlọ́run , láti fi àjàgà bọ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn lọ́rùn, èyí àwọn baba wa àti àwa ? 11 Ṣùgbọ́n àwa gbàgbọ́ nípa oore-ọ̀fẹ́ Olúwa Jesu àwa ó , gẹ́gẹ́ àwọn."

12 Gbogbo àjọ dákẹ́, wọ́n fi etí Barnaba àti Paulu, wọn ń ròyìn iṣẹ́ ìyanu àti iṣẹ́ àmì Ọlọ́run ti ọwọ́ wọn ṣe láàrín àwọn aláìkọlà. 13 Lẹ́yìn wọn dákẹ́, Jakọbu dáhùn, , "Ará, gbọ́ tèmi, 14 Simeoni ti ròyìn Ọlọ́run ti kọ́kọ́ bojú wo àwọn aláìkọlà, láti yàn ènìyàn nínú wọn fún orúkọ rẹ̀. 15 Báyìí ni ̀rọ̀ àwọn wòlíì ṣe déédé; a ti kọ̀rẹ̀ :

16 15.16-18: Am 9.11-12; Jr 12.15; Isa 45.21. " Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí ni èmi ó padà,

èmi ó tún àgọ́ Dafidi pa ó ti lulẹ̀:

èmi ó tún ahoro rẹ̀ kọ́,

èmi ó gbé e .

17 àwọn ènìyàn ìyókù máa Olúwa,

àti gbogbo àwọn kèfèrí, lára ẹni a ń pe orúkọ mi,

ni Olúwa , ta ni ó ń ṣe nǹkan wọ̀nyí,

18 ẹni ó sọ gbogbo nǹkan wọ̀nyí di mímọ́ láti ọjọ́ pípẹ́ .

19 "Ǹjẹ́ ìmọ̀ràn tèmi ni , a máa ṣe yọ àwọn ti aláìkọlà ti ó yípadà Ọlọ́run lẹ́nu. 20 Ṣùgbọ́n a kọ̀si wọn, wọ́n fàsẹ́yìn kúrò nínú oúnjẹ a ṣe fún òrìṣà, àti kúrò nínú àgbèrè, àti nínú ̀jẹ̀. 21 Nítorí òfin Mose nígbà àtijọ́ ṣá a ti ń wàásù rẹ̀, ni ìlú gbogbo, a máa ń á nínú Sinagọgu ni ọjọọjọ́ ìsinmi."

Ìwé àwọn àjọ ìgbìmọ̀ kọ àwọn onígbàgbọ́ aláìkọlà

22 Nígbà án ni ó tọ́ lójú àwọn aposteli, àti àwọn alàgbà pẹ̀gbogbo ìjọ, láti yan ènìyàn nínú wọn, àti láti rán wọ́n lọ Antioku pẹ̀Paulu àti Barnaba: Judasi ti a ń àpèlé rẹ̀ Barsaba, àti Sila, ẹni ó lórúkọ nínú àwọn arákùnrin. 23 Wọn kọ ìwé wọn lọ́wọ́ báyìí ,

Àwọn aposteli, àti àwọn alàgbà,

ó jẹ́ ti aláìkọlà ó Antioku, àti Siria, àti Kilikia.

24 Níwọ́n àwa ti gbọ́ , àwọn kan ti ó ti ̀dọ̀ wa jáde ń fi ̀rọ̀ yọ yín lẹ́nu, wọ́n ń yín ọkàn padà (, gbọdọ̀ ṣàìmá kọ ilà, àti ṣàìmá pa òfin Mose mọ́), ẹni àwa fún àṣẹ. 25 Ó yẹ lójú àwa, wa ti fi ìmọ̀ ṣọ̀kan láti yan ènìyàn láti rán wọn yín, pẹ̀Barnaba àti Paulu àwọn olùfẹ́ wa. 26 Àwọn ọkùnrin ti ó fi ọkàn wọn wéwu nítorí orúkọ Olúwa wa Jesu Kristi. 27 Nítorí náà àwa rán Judasi àti Sila àwọn yóò fi ̀rọ̀ ẹnu sọ ohun kan náà fún yín. 28 Nítorí ó dára lójú ̀Mímọ́, àti lójú wa, a ṣe di ẹrù le é yin lórí, ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí ó ṣe pàtàkì; 29 í ̀yin fàsẹ́yìn kúrò nínú ẹran ti à pa bọ òrìṣà, àti nínú ̀jẹ̀ àti nínú ohun ìlọ́lọ́rùnpa, àti nínú àgbèrè. ̀yin pa ara yín mọ́ kúrò, ̀yin ó ṣe rere.

Àlàáfíà.

30 Ǹjẹ́ nígbà wọ́n fi wọ́n sílẹ̀ láti lọ, wọ́n sọ̀kalẹ̀ si Antioku. Nígbà wọn àwọn ìjọ papọ̀, wọn fi ìwé náà fún wọn. 31 Nígbà wọn á, wọ́n yọ̀ fún ìtùnú náà. 32 Judasi àti Sila tìkára wọn ti jẹ́ wòlíì pẹ̀, wọ́n fi ̀rọ̀ púpọ̀ gba àwọn arákùnrin níyànjú, wọ́n wọn lọ́kàn le. 33 Nígbà wọn pẹ́, díẹ̀, àwọn arákùnrin rán wọn padà lọ ni àlàáfíà ̀dọ̀ àwọn ó rán wọn .15.33 Àwọn àkọsílẹ̀ àtijọ́ kan se àfikún ọ̀rọ̀ yìí wá,34 ṣùgbọ́n ó wu Sila láti gbé ibẹ̀. 35 Paulu àti Barnaba dúró díẹ̀ ni Antioku, wọ́n ń kọ́ni, wọ́n ń wàásù ̀rọ̀, Olúwa, àti àwọn púpọ̀ mìíràn pẹ̀wọn.

Ìjà láàrín Paulu àti Barnaba

36 Lẹ́yìn ọjọ́ mélòó kan, Paulu sọ fún Barnaba , "Jẹ́ a tún padà lọ bẹ àwọn arákùnrin wa , wọn ti ń ṣe ni ìlú gbogbo àwa ti wàásù ̀rọ̀ Olúwa." 37 Barnaba pinnu rẹ̀ láti Johanu lọ pẹ̀wọn, ẹni àpèlé rẹ̀ ń jẹ́ Marku. 38 Ṣùgbọ́n Paulu , yẹ láti un lọ pẹ̀wọn, ẹni ó fi wọn sílẹ̀ ni Pamfilia, wọn lọ iṣẹ́ náà. 39 Ìjà náà pọ̀ bẹ́̀, wọn ya ara wọn méjì, Barnaba mu Marku ó tẹ ọkọ́ létí lọ Saipurọsi. 40 Ṣùgbọ́n Paulu yan Sila, ó lọ, a ti fi oore-ọ̀fẹ́ Olúwa lọ́wọ́ láti ̀dọ̀ àwọn arákùnrin. 41 Ó la Siria àti Kilikia lọ, ó ń ìjọ ọkàn le.

Veja também