Pular para o conteúdo
Publicidade

Atos 16

Paulu àti Sila nínú túbú

16 àwa n lọ ibi àdúrà náà, ọmọbìnrin kan o ̀àfọ̀ṣẹ, pàdé wa, ẹni ó fi àfọ̀ṣẹ èrè púpọ̀ fún àwọn ̀rẹ̀. 17 Òun náà ni ó ń tọ Paulu àti àwa lẹ́hìn, ó ń kígbe, , "Àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ni ìránṣẹ́ Ọlọ́run ̀gá-ògo, ń kéde ̀ìgbàlà fún yin!" 18 Ó ń ṣe èyí lọ́jọ́ púpọ̀, ṣùgbọ́n nígbà inú Paulu bàjẹ́, ó yípadà, ó fún ̀náà , "Mo pàṣẹ fún orúkọ Jesu Kristi o jáde kúrò lára rẹ̀!" Ó jáde ni wákàtí kan náà.

19 Nígbà àwọn ̀rẹ̀ i , ìgbẹ́kẹ̀èrè wọn pin, wọ́n Paulu àti Sila, wọn wọ́ wọn lọ ọjà tọ àwọn aláṣẹ lọ. 20 Nígbà wọ́n wọn tọ àwọn onídàájọ́ lọ, wọ́n , "Àwọn ọkùnrin wọ̀nyí í ṣe Júù, wọ́n ń yọ ìlú wa lẹ́nu jọjọ, 21 wọ́n ń kọ́ni àṣà yẹ fún wa, àwa ẹni í ṣe ara Romu, láti gbà àti láti tẹ̀."

22 16.22-23: 2Kọ 11.25. ̀pọ̀ ènìyàn jùmọ̀ dìde Paulu àti Sila. Àwọn olórí wọ́n aṣọ ya, wọ́n pàṣẹ , ki a fi ̀gọ̀ wọ́n. 23 Nígbà wọ́n wọ́n púpọ̀, wọ́n sọ wọ́n sínú túbú, wọ́n kìlọ̀ fún onítúbú ó pa wọ́n mọ́ dáradára. 24 Nígbà ó gbọ́ irú ìkìlọ̀ bẹ́̀, ó sọ̀ wọ́n sínú túbú inú lọ́hùn, ó kan àbà mọ wọ́n lẹ́sẹ̀.

25 Ṣùgbọ́n láàrín ̀gànjọ́ Paulu àti Sila ń gbàdúrà, wọ́n ń kọrin ìyìn si Ọlọ́run, àwọn ara túbú ń tẹ́wọn. 26 Lójijì ilẹ̀ mímì ńlá mi, bẹ́̀ ìpìlẹ̀ ilé túbú tìtì: lọ́gán, gbogbo ìlẹ̀kùn ṣí, ìdè gbogbo wọn sílẹ̀. 27 Nígbà onítúbú si tají, o ri , àwọn ìlẹ̀kùn túbú ṣí sílẹ̀, ó fa idà rẹ̀ yọ, ó fẹ́ pa ara rẹ̀, ó ṣe àwọn ara túbú ti sálọ. 28 Ṣùgbọ́n Paulu gbé ohun rẹ̀ sókè, , "ṣe pa ara rẹ lára: nítorí gbogbo wa ń bẹ níhìn-ín yìí!"

29 Nígbà ó béèrè iná, ó bẹ́ wọ inú ilé, ó ń wárìrì, ó wólẹ̀ níwájú Paulu àti Sila. 30 Ó wọn jáde, ó , "Alàgbà, kín ni ki èmi ṣe ki n ?"

31 Wọ́n fún un , "Gbá Jesu Kristi Olúwa gbọ́, a ó gbà ́ , ìwọ àti àwọn ará ilé rẹ pẹ̀." 32 Wọ́n sọ ̀rọ̀ Olúwa fún un, àti fún gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀. 33 Ó wọn wákàtí náà lóru, ó wẹ ọgbẹ́ wọn; a bamitiisi rẹ̀, àti gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀ lójúkan náà. 34 Ó wọn ilé rẹ̀, ó gbé oúnjẹ kalẹ̀ níwájú wọn, ó yọ̀ gidigidi pẹ̀gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀, nítorí ó gba Ọlọ́run gbọ́.

35 Ṣùgbọ́n nígbà ilẹ̀ mọ́, àwọn onídàájọ́ rán àwọn ọlọ́pàá , "àwọn ènìyàn náà sílẹ̀." 36 Onítúbú sọ ̀rọ̀ náà fún Paulu, , "Àwọn onídàájọ́ ránṣẹ́ á da ìwọ àti Sila sílẹ̀. Ǹjẹ́ nísinsin yìí jáde máa lọ àlàáfíà."

37 Ṣùgbọ́n Paulu fún wọn , "Wọ́n ni gbangba, wọ́n sọ sínú túbú ni àìjẹ̀bi, àwa ẹni ì ṣe ara Romu. Ṣe nísinsin yìí wọ́n fẹ́ jáde níkọ̀kọ̀? Rara! Ṣùgbọ́n àwọn tìkára wọn wa jáde!"

38 Àwọn ọlọ́pàá sọ ̀rọ̀ wọ̀nyí fún àwọn onídàájọ́: ̀wọ́n, nígbà wọ́n gbọ́ ará Romu ni Paulu àti Sila. 39 Wọ́n , wọ́n ṣìpẹ̀ lọ́dọ̀ wọ́n, wọn wọn jáde, wọ́n bẹ̀ wọ́n , ki wọn jáde kúrò ni ìlú náà. 40 Paulu àti Sila jáde nínú túbú, wọ́n wọ ilé Lidia lọ, nígbà wọn àwọn arákùnrin, wọ́n wọ́n nínú, wọn jáde kúrò.

Veja também