Publicidade

Colossenses 3

Àwọn òfin fún ìgbé ayé ìwà mímọ́

1 Níwọ́n ìgbà a ti yín dìde pẹ̀Kristi máa ṣàfẹ́àwọn nǹkan ń bẹ lókè, níbi Kristi gbé ó jókòó ọwọ́ ̀tún Ọlọ́run. 2 máa ronú àwọn ohun ń bẹ lókè í ṣe àwọn nǹkan ń bẹ ayé. 3 Nítorí ̀yin ti , a fi ìyè yín pamọ́ pẹ̀Kristi nínú Ọlọ́run. 4 Nígbà Kristi, ẹni í ṣe ìyè yín yóò farahàn, nígbà náà ni ̀yin pẹ̀yóò farahàn pẹ̀rẹ̀ nínú ògo.

5 máa pa ̀ara yín ń bẹ ayé run: àgbèrè, panṣágà, ìwà àìmọ́, ìfẹ́kúfẹ̀́ àti ìwọra, nítorí ìwọ̀nyí jásí ìbọ̀rìṣà. 6 Lórí àwọn wọ̀nyí ni ìbínú Ọlọ́run ń bọ̀ . 7 máa ń ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí tẹ́lẹ̀ nígbà ìgbé ayé yín jẹ́ apá kan ayé yìí. 8 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, gbọdọ̀ fi àwọn wọ̀nyí sílẹ̀: ìbínú, ìrunú, àrankàn, fífi ̀rọ̀-kẹ́lẹ́-ba-tẹni-jẹ́ àti ̀rọ̀ èérí kúrò ètè yín. 9 ṣe purọ́ fún ara yín, níwọ̀n ìgbà ti bọ́ ògbólógbòó ara yín pẹ̀ìṣe rẹ̀ sílẹ̀, 10 ti gbé ìgbé ayé tuntun wọ̀, èyí a sọ di tuntun nínú ìmọ̀ ìbámu pẹ̀àwòrán ẹni ó a. 11 Níbi gbé Giriki tàbí Júù, ìkọlà tàbí aláìkọlà, aláìgbédè, ara Skitia, ẹrú tàbí òmìnira, ṣùgbọ́n Kristi ni ohun gbogbo nínú ohun gbogbo.

12 Nítorí náà, àyànfẹ́ Ọlọ́run, ẹni mímọ́ àti olùfẹ́, gbé ọkàn ìyọ́wọ̀, ìṣoore, ìrẹ̀lẹ̀, inú tútù àti sùúrù. 13 máa fi ara á fún ara yín, máa dáríjì ara yín ẹnikẹ́ni ̀sùn ẹnìkan: Kristi ti dáríjì yín, gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni ̀yin ó máa ṣe pẹ̀. 14 Àti borí gbogbo nǹkan wọ̀nyí, gbé ìfẹ́ wọ̀, í ṣe àmùrè ìwà pípé.

15 jẹ́ àlàáfíà Ọlọ́run ó máa ṣe àkóso ọkàn yín, sínú èyí a yín pẹ̀nínú ara kan; máa dúpẹ́. 16 jẹ́ ̀rọ̀ Kristi máa gbé inú yín ̀pọ̀lọpọ̀ nínú ọgbọ́n gbogbo; máa kọ́ , máa gba ara yín níyànjú nínú Saamu, àti orin ìyìn, àti orin ̀, máa kọrin Ọlọ́run ọkàn ọpẹ́. 17 Ohunkóhun ̀yin ń ṣe ̀rọ̀ tàbí ìṣe, máa ṣe gbogbo wọn orúkọ Jesu Olúwa, máa fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run Baba nípasẹ̀ rẹ̀.

Àwọn òfin fún agbo ilé Kristi

18 ̀yin aya, máa tẹríba fún àwọn ọkọ yín, gẹ́gẹ́ ó ti yẹ nínú Olúwa.

19 ̀yin ọkọ, máa fẹ́ràn àwọn aya yín, ṣe korò wọn.

20 ̀yin ọmọ máa gbọ́ ti àwọn òbí yín ohun gbogbo, nítorí èyí dára gidigidi nínú Olúwa.

21 ̀yin baba, ṣe àwọn ọmọ yín bínú, wọn á rẹ̀wẹ̀.

22 ̀yin ẹrú, gbọ́ ti àwọn olówó yín nípa ti ara ohun gbogbo; í ṣe àrọ́júṣe, àwọn aláṣehàn ènìyàn; ṣùgbọ́n òtítọ́ inú, ìbẹ̀Ọlọ́run. 23 Ohunkóhun ̀yin ń ṣe, máa fi tọkàntọkàn ṣe é fún Olúwa, í ṣe fún ènìyàn; 24 mọ̀ lọ́wọ́ Olúwa ni ̀yin ó gba èrè, nítorí ̀yin ń sìn Olúwa Kristi. 25 Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ó ṣe àìṣòdodo, yóò gbà á padà nítorí àìṣòdodo náà ó ti ṣe: ṣí ojúsàájú.

Veja também

Publicidade
Colossenses
Ver todos os capítulos de Colossenses
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-