Publicidade

Daniel 11

1 ọdún kìn-ín-ní Dariusi ará Media, mo dúró láti í lẹ́yìn àti láti dáàbò ó.)

Àwọn ọba gúúsù àti àríwá

2 "ìsinsin yìí, mo sọ òtítọ́ fún ọba mẹ́ta yóò dìde i Persia, àti ̀kẹrin yóò jẹ́ ọlọ́rọ̀ ju gbogbo wọn lọ. ó ti di alágbára nípa ọrọ̀ rẹ̀, yóò ru gbogbo wọn sókè lòdì ìjọba Giriki. 3 Nígbà náà ni ọba alágbára kan yóò fi ara hàn, yóò ṣe àkóso pẹ̀agbára ńlá, yóò ṣe ó ti ú. 4 Lẹ́yìn ìgbà ó fi ara hàn tán, ìjọba rẹ̀ yóò fọ́, yóò pín mẹ́rin orígun mẹ́rẹ̀̀rin ayé, ìjọba náà ṣọ́wọ́ àwọn ìran rẹ̀ tàbí ó agbára ó ń tẹ́lẹ̀, nítorí, a ó fa ìjọba rẹ̀ tu a ó fi fún àwọn mìíràn.

5 "Ọba ìhà gúúsù yóò di alágbára ṣùgbọ́n ̀kan lára àwọn aláṣẹ rẹ̀ yóò di alágbára ú lọ, yóò ṣe àkóso ìjọba rẹ̀ pẹ̀agbára ńlá. 6 Lẹ́yìn ọdún púpọ̀ wọn yóò májẹ̀àlàáfíà, ọmọbìnrin ọba gúúsù yóò lọ ̀dọ̀ ọba àríwá láti a májẹ̀àlàáfíà, ṣùgbọ́n òun yóò di agbára apá a rẹ̀ , bẹ́̀ ni òun yóò dádúró, ṣùgbọ́n a ó tẹrí i rẹ̀ ba àti àwọn ó un , àti ọmọ ó , àti ẹni ó ń mu lọ́kàn le gbogbo àkókò wọ̀nyí.

7 "̀kan lára àwọn ìdílé e rẹ̀, ọmọbìnrin ọba gúúsù yóò dìde láti gba ipò o rẹ̀. Yóò kọlu ogun ọba àríwá, yóò odi alágbára; yóò wọn yóò borí. 8 Yóò gba òrìṣà wọn, ère dídá àti ohun èlò oníye lórí ti fàdákà àti ti wúrà, yóò wọn lọ Ejibiti. Fún ọdún díẹ̀ yóò fi ọba àríwá lọ́rùn sílẹ̀. 9 Nígbà náà, ni ọba àríwá yóò gbógun ti ilẹ̀ ọba, gúúsù, ṣùgbọ́n yóò padà Orílẹ̀-èdè, òun fúnra rẹ̀. 10 Àwọn ọmọ rẹ̀ yóò múra ogun wọn yóò ogun ńlá jọ, èyí a ó gbá lọ àgbàrá omi ńlá, yóò gbá a lọ títí ìlú olódi rẹ̀.

11 "Nígbà náà ni ọba gúúsù yóò jáde pẹ̀ìbínú, yóò ọba àríwá , ẹni yóò ọmọ-ogun púpọ̀ jọ, ṣùgbọ́n ọba gúúsù yóò borí i wọn. 12 Nígbà a ogun náà lọ, ọba gúúsù yóò kún fún agbára, yóò pa ẹgbẹẹgbẹ̀rún ìpakúpa síbẹ̀ yóò ṣẹ́gun. 13 Nítorí ọba àríwá yóò lọ ogun mìíràn jọ, ó pọ̀ ju ti àkọ́kọ́ lẹ́yìn ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún, yóò jáde pẹ̀̀pọ̀lọpọ̀ ogun ó ti dira ogun fún dáradára.

14 "àkókò ìgbà náà, ni ̀pọ̀lọpọ̀ yóò dìde ọba gúúsù. Àwọn ọlọ̀tẹ̀ nínú àwọn ènìyàn an rẹ̀ yóò ṣọ̀tẹ̀ ìmúṣẹ ìran náà, ṣùgbọ́n wọn yóò borí. 15 Nígbà náà ni ọba àríwá yóò yóò gbé ogun í, yóò ìlú olódi. Ogun ọba gúúsù agbára láti kọjú ìjà i; bẹ́̀ ni àwọn ̀wọ́ ogun dára agbára láti dúró. 16 Ẹni ó gbóguntì í yóò máa ṣe ó ti ú, ṣí ẹni yóò le è dojúkọ ́. Yóò fún ara rẹ̀ ibùjókòó ilẹ̀ ó dára, yóò agbára láti á jẹ́. 17 Yóò pinnu láti pẹ̀agbára ìjọba rẹ̀, yóò májẹ̀àlàáfíà pẹ̀ọba gúúsù yóò fi ọmọbìnrin rẹ̀ fún un láti fẹ́ ìyàwó nítorí ó gba ìjọba, ṣùgbọ́n ète rẹ̀ yìí yóò dúró tàbí ṣe ìrànlọ́wọ́ fún un. 18 Nígbà náà ni yóò ara padà ilẹ̀ etí Òkun, yóò ̀pọ̀lọpọ̀, ṣùgbọ́n aláṣẹ kan yóò òpin àfojúdi rẹ̀, yóò àfojúdi rẹ̀ padà orí rẹ̀. 19 Lẹ́yìn èyí, yóò padà ìlú olódi ti orílẹ̀-èdè òun fúnra rẹ̀, ṣùgbọ́n yóò kọsẹ̀ yóò ṣubú, a yóò i mọ́.

20 "Arọ́rẹ̀ yóò rán agbowó orí kan jáde láti fi ìdí ipò ọlá ọba múlẹ̀ ṣùgbọ́n ìwọ̀n ọdún díẹ̀, a ó pa á run, yóò jẹ́ nípa ìbínú tàbí nínú ogun.

21 "Ẹni níláárí kan yóò rọ́rẹ̀, ẹni a ì fi ọlá ọba fún . Yóò gbógun ìjọba nígbà ọkàn àwọn ènìyàn balẹ̀ láìbẹ̀, yóò gbà á pẹ̀àrékérekè. 22 Nígbà náà, ni a ó gbà ogunlọ́gọ̀ ogun kúrò níwájú u rẹ̀, pẹ̀òun àti ọmọ-aládé ti májẹ̀náà ni a ó parun. 23 Lẹ́yìn ó ṣe ìpinnu pẹ̀u rẹ̀, yóò hùwà ̀tàn, pẹ̀ìwọ̀nba ènìyàn kékeré ni yóò gba ìjọba. 24 Nígbà àwọn agbègbè ó lọ́rọ̀ gidigidi láìbẹ̀ni yóò gbóguntì wọ́n, yóò ṣe ohun baba rẹ̀ tàbí baba ńlá rẹ̀ ṣe , yóò pín ìkógun ẹrù àti ọrọ̀ fún àwọn ọmọ lẹ́yìn in rẹ̀. Yóò pète àti bi àwọn ìlú olódi ṣubú, ṣùgbọ́n fún ìgbà díẹ̀ ni.

25 "Pẹ̀ogun púpọ̀, yóò ru agbára rẹ̀ àti ìgboyà rẹ̀ sókè ọba gúúsù. Ọba gúúsù yóò dìde ogun pẹ̀̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ-ogun ó lágbára gidigidi, ṣùgbọ́n le è dúró, nítorí ̀tẹ̀ ó gbèrò i. 26 Àwọn ó jẹ nínú oúnjẹ ọba yóò gbìyànjú láti parun, a ó gbá ogun rẹ̀ dànù, ̀pọ̀lọpọ̀ ni yóò ṣubú ogun. 27 Àwọn ọba méjèèjì, ọkàn wọn tẹ̀ búburú, wọn yóò jókòó lórí tábìlì kan, wọn yóò máa parọ́ ara wọn, ṣùgbọ́n yọrí nǹkan kan nítorí òpin yóò àsìkò a yàn. 28 Ọba àríwá yóò padà ilẹ̀ rẹ̀ pẹ̀ọrọ̀ púpọ̀, ṣùgbọ́n ọkàn rẹ̀ yóò lòdì májẹ̀mímọ́, yóò ṣiṣẹ́ lòdì i, yóò padà orílẹ̀-èdè òun fúnra rẹ̀.

29 "àsìkò a yàn, yóò gbógun gúúsù lẹ́̀kan i, ṣùgbọ́n ìgbà àyọríṣí yóò yàtọ̀ ti ìṣáájú. 30 Nítorí , ọkọ̀ ojú omi àwọn ilẹ̀ etídò ìwọ̀-oòrùn yóò takò ó, ọkàn rẹ̀ yóò pami. Nígbà náà, ni yóò padà, yóò bínú májẹ̀mímọ́, yóò padà, yóò fi ojúrere hàn àwọn ó kọ májẹ̀mímọ́ náà.

31 11.31: Da 9.27; 12.11; Mt 24.15; Mk 13.14. "Agbára ọmọ-ogun rẹ̀ yóò dìde láti ba ohun mímọ́ ilé olódi tẹmpili jẹ́, yóò pa ẹbọ ojoojúmọ́ rẹ́. Nígbà náà ni wọn yóò gbé ìríra ó fa ìsọdahoro kalẹ̀. 32 Pẹ̀irú àwọn ń ṣe búburú májẹ̀yóò fi ̀rọ̀ ìpọ́nni ṣọ̀tẹ̀, ṣùgbọ́n, àwọn ó mọ Ọlọ́run wọn yóò ọkàn le. Wọn yóò máa ṣe iṣẹ́ agbára.

33 "Àwọn ó mòye yóò máa kọ́ ̀pọ̀lọpọ̀, ṣùgbọ́n fún ìgbà díẹ̀, wọn yóò máa ṣubú nípa idà tàbí a wọn tàbí ìgbèkùn tàbí nípa ìkógun. 34 Nígbà wọ́n ṣubú, wọn yóò ìrànlọ́wọ́ díẹ̀, ̀pọ̀ àwọn ṣe aláìṣòótọ́ yóò darapọ̀ mọ́ wọn. 35 Lára àwọn ó mòye yóò kọsẹ̀, nítorí a ba à tún wọn ṣe, wọ́n di mímọ́ àti aláìlábàwọ́n títí di ìgbà ìkẹyìn nítorí yóò àkókò a yàn.

Ọba ó gbé ara rẹ̀ ga

36 "Ọba yóò ṣe ó ti ú yóò gbé ara rẹ̀ ga, ju gbogbo òrìṣà lọ, yóò máa sọ àwọn ̀rọ̀ kò-ṣe-é-gbọ́-létí Ọlọ́run àwọn Ọlọ́run, yóò máa yege títí àkókò ìbínú yóò fi parí, nítorí ohun a ti pinnu yóò ṣẹlẹ̀. 37 Òun ka òrìṣà àwọn baba rẹ̀ tàbí èyí àwọn fẹ́, òun ka nǹkan kan , ṣùgbọ́n yóò gbé ara rẹ̀ ga ju gbogbo wọn lọ. 38 Ṣùgbọ́n dípò wọn, yóò bu ọlá fún òrìṣà àwọn ìlú olódi: òrìṣà àwọn baba rẹ̀ mọ̀ ni yóò bu ọlá fún pẹ̀wúrà àti fàdákà, pẹ̀òkúta iyebíye àti ̀bùn ó lówó lórí. 39 Yóò kọlu àwọn ìlú olódi ó lágbára pẹ̀ìrànlọ́wọ́ òrìṣà àjèjì, yóò bu ọláńlá fún ẹni ó jẹ́wọ́ rẹ̀. Yóò wọn ṣe alákòóso lórí ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, yóò pín ilẹ̀ náà fún wọn gẹ́gẹ́ èrè.

40 "ìgbà ìkẹyìn, ọba gúúsù yóò gbé ogun de i, ọba àríwá yóò jáde ìjì láti kọlù ú pẹ̀u kẹ̀kẹ́ ogun àti ẹlẹ́ṣin àti ̀pọ̀lọpọ̀ ọkọ̀ ojú omi. Yóò gbógun wọ orílẹ̀-èdè púpọ̀, yóò bo wọn mọ́lẹ̀ ìkún omi. 41 Bẹ́̀ ni yóò tún gbógun ti ilẹ̀ ológo náà pẹ̀, ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè yóò ṣubú, ṣùgbọ́n Edomu, Moabu àti àwọn olórí Ammoni yóò bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀. 42 Yóò lo agbára rẹ̀ lórí ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè; Ejibiti yóò . 43 Yóò gba àkóso ìṣúra wúrà àti fàdákà àti gbogbo ọrọ̀ Ejibiti, pẹ̀ti Libia àti Kuṣi nígbà ó wọn tẹríba. 44 Ṣùgbọ́n ìròyìn láti ìlà-oòrùn àti láti ìwọ̀-oòrùn yóò ìdáríjì a, yóò fi ìbínú ńlá jáde lọ láti parun, àti láti pa ̀pọ̀lọpọ̀ run pátápátá. 45 Yóò pàgọ́ rẹ̀ láàrín Òkun kọjú àárín òkè mímọ́ ológo. Síbẹ̀ yóò òpin rẹ̀, ẹnìkan ràn án lọ́wọ́.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-