Publicidade

Daniel 12

Ìgbà ìkẹyìn

1 12.1: Mt 24.21; Mk 13.19; If 12.7; 16.18. "àkókò náà, ni Mikaeli, ọmọ-aládé ńlá, ẹni o ń dáàbò bo àwọn ènìyàn an rẹ̀ yóò dìde. Àkókò ìpọ́njú yóò , irú èyí ì ṣẹlẹ̀ láti ìbẹ̀rẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè títí di àkókò náà. Ṣùgbọ́n àkókò náà àwọn ènìyàn rẹ̀, gbogbo àwọn a ti orúkọ wọn nínú ìwé ni a ó gbàlà. 2 12.2: Mt 25.46.̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ó sùn nínú erùpẹ̀ ilẹ̀ ni yóò : àwọn mìíràn ìyè àìnípẹ̀kun, àwọn tókù ìtìjú àti ̀gàn àìnípẹ̀kun. 3 12.3: Mt 13.43.Àwọn ó jẹ́ ọlọ́gbọ́n yóò máa tàn ìmọ́lẹ̀ ̀run, àti àwọn ó ń tọ́nisọ́òdodo, yóò máa tàn ìràwọ̀ láé àti láéláé.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_15-35-42-