Publicidade

Daniel 2

Àlá Nebukadnessari

1 ọdún kejì ìjọba Nebukadnessari, ó àlá, èyí ó ọkàn an rẹ̀ dàrú, le è sùn. 2 Nígbà náà ni ọba yára pe àwọn onídán, àwọn aláfọ̀ṣẹ, àwọn oṣó àti àwọn awòràwọ̀; àwọn ìmọ̀ àti àṣírí i títúmọ̀ ìràwọ̀, ọba wọ́n wọn sọ àlá ó . Nígbà wọ́n , wọ́n dúró níwájú ọba, 3 ọba fún wọn , "Mo ti àlá kan èyí ó ọkàn mi dàrú, mo fẹ́ mọ ìtumọ̀ àlá náà."

4 Nígbà náà ni àwọn awòràwọ̀ ọba lóhùn èdè Aramaiki , "ọba ó pẹ́! Sọ àlá yìí fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ àwa yóò sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún ."

5 Ọba àwọn awòràwọ̀ lóhùn , "Ohun náà ti kúrò lórí mi, ̀yin sọ àlá náà àti ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi, èmi yóò e yín wẹ́wẹ́, ilé e yín yóò di ààtàn. 6 Ṣùgbọ́n ̀yin sọ àlá náà àti ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi, èmi yóò fún un yín ̀bùn, ọrẹ àti ọláńlá ó pọ̀. Nítorí náà, sọ àlá náà àti ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi."

7 Lẹ́̀kan i, "Wọ́n tún dáhùn , jẹ́ ọba sọ àlá náà fún ìránṣẹ́ rẹ̀, àwa yóò túmọ̀ rẹ̀."

8 Nígbà náà ni ọba sọ , "Èmi mọ̀ dájú ̀yin fẹ́ fi àkókò ṣòfò nítorí ̀yin ti mọ̀ nǹkan ti lọ orí mi. 9 ̀yin sọ àlá mi, ìjìyà kan ṣoṣo fún un yín. ̀yin ti gbèrò láti pa irọ́ àti láti sọ àwọn ̀rọ̀ ti ó si ni lọ́fún mi, títí nǹkan yóò fi wọ́. Nítorí náà rọ́ àlá náà fún mi, èmi yóò mọ̀ túmọ̀ rẹ̀ fún mi."

10 Àwọn awòràwọ̀ ọba lóhùn , "ènìyàn kan ayé ó sọ nǹkan ọba béèrè! ọba náà ó ti ó tóbi àti ó lágbára , í béèrè irú nǹkan bẹ́̀ lọ́wọ́ àwọn onídán tàbí aláfọ̀ṣẹ tàbí awòràwọ̀. 11 Nǹkan ọba béèrè yìí ṣòro púpọ̀. ẹni ó fihan ọba àfi àwọn òrìṣà, wọn í gbé láàrín ènìyàn."

12 Èyí ọba bínú, ó kanra, nítorí náà ó pàṣẹ a pa gbogbo àwọn amòye Babeli run. 13 Nítorí náà àṣẹ yìí jáde lọ a pa àwọn amòye, wọ́n ránṣẹ́ pe Daniẹli pẹ̀àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ láti pa wọ́n.

14 Nígbà Arioku, olórí àwọn olùṣọ́ ọba, jáde láti lọ pa àwọn amòye Babeli, Daniẹli sọ̀rọ̀ fún un pẹ̀ọgbọ́n àti òye. 15 Ó béèrè lọ́wọ́ olórí àwọn olùṣọ́ ọba , "Èéṣe àṣẹ ọba fi kánkán bẹ́̀?" Arioku ṣe àlàyé ̀rọ̀ náà fún Daniẹli. 16 Nígbà náà ni Daniẹli wọlé tọ ọba lọ, ó tọrọ ọba fún òun ààyè, òun yóò fi ìtumọ̀ àlá náà hàn fún ọba.

17 Nígbà náà ni Daniẹli padà lọ ilé e rẹ̀, ó sọ fún àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ Hananiah, Miṣaeli àti Asariah. 18 Ó sọ fún wọn wọn béèrè fún àánú Ọlọ́run, Olúwa ̀run, nítorí àṣírí yìí, Daniẹli pẹ̀àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ ba ṣègbé pẹ̀àwọn ọlọ́gbọ́n Babeli yòókù, ó Babeli. 19 òru, àṣírí náà hàn Daniẹli ojú ìran. Nígbà náà ni Daniẹli fi ògo fún Ọlọ́run ̀run 20 Daniẹli :

"Ọpẹ́ ni fún orúkọ Ọlọ́run láé àti láéláé;

tirẹ̀ ni ọgbọ́n àti agbára.

21 Ó ìgbà àti àkókò padà;

ó ọba jẹ, ó ń wọn kúrò.

Ó fún àwọn amòye ọgbọ́n

àti ìmọ̀ fún àwọn ó òye.

22 Ó fi ohun ìjìnlẹ̀ àti àṣírí hàn;

ó mọ ohun ó pamọ́ nínú òkùnkùn

àti ̀dọ̀ rẹ̀ ni ìmọ́lẹ̀ .

23 Mo dúpẹ́, mo fi ìyìn fún , ìwọ Ọlọ́run àwọn baba mi:

ó ti fún mi ọgbọ́n àti agbára

ó ti fi àwọn nǹkan a béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ hàn fún mi

nítorí ìwọ ti fi àlá ọba hàn ."

Daniẹli túmọ̀ àlá

24 Nígbà náà ni Daniẹli tọ́ Arioku lọ, ẹni ọba yàn láti pa àwọn amòye Babeli run, Daniẹli fún un , "ṣe pa àwọn amòye Babeli run. mi lọ ̀dọ̀ ọba, èmi yóò sísọ ìtumọ̀ àlá rẹ̀ fún un."

25 Lẹ́sẹ̀kan náà, Arioku yára Daniẹli lọ iwájú ọba, ó sọ fún ọba , "Èmi ti ọkùnrin kan lára àwọn àjèjì ó láti Juda, ẹni ó sọ ìtumọ̀ àlá náà fún ọba."

26 Ọba béèrè lọ́wọ́ Daniẹli ẹni a tún ń Belṣassari , "Ṣé ìwọ sọ ohun mo nínú àlá mi àti ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi?"

27 Daniẹli ọba lóhùn , "awòràwọ̀ kan, apògèdè, onídán tàbí aláfọ̀ṣẹ ó ṣe àlàyé àṣírí ọba béèrè fún 28 ṣùgbọ́n, Ọlọ́run kan ń bẹ ̀run ó ń fi àṣírí hàn. Ó ti fihan ọba Nebukadnessari, ohun yóò ṣẹlẹ̀ ìkẹyìn ọjọ́. Àlá àti ìran o nígbà o dùbúlẹ̀ lórí ibùsùn rẹ ni ìwọ̀nyí:

29 "Ọba, ìwọ ṣe sùn sórí ibùsùn rẹ, bẹ́̀ ni ọkàn rẹ ń ro àwọn ohun ń bọ̀, olùfihàn àṣírí ń fi ohun yóò ṣẹlẹ̀ fún . 30 Ṣùgbọ́n fún èmi, a fi àṣírí yìí hàn , í ṣe mo ọgbọ́n ó pọ̀ ju ti alààyè kankan lọ, ṣùgbọ́n nítorí ọba mọ ìtumọ̀ àlá àti ó mọ ohun ó ọkàn rẹ̀.

31 "Ìwọ ọba ń wo, ère ńlá kan ó dúró níwájú rẹ, ère náà ga, ó dára láti , ìrísí i rẹ̀ ba ni lẹ́jọjọ. 32 Orí ère náà jẹ́ kìkì wúrà, àyà rẹ̀ àti ọwọ́ rẹ̀ jẹ́ fàdákà, inú àti ̀gbẹ́ itan rẹ̀ jẹ́ idẹ, 33 àwọn ẹsẹ̀ rẹ̀ jẹ́ irin, àwọn àtẹ́lẹsẹ̀ rẹ̀ jẹ́ apá kan irin àti apá kan amọ̀. 34 ó ṣe ń , òkúta kan , láti ọwọ́ ẹnìkankan. Ó kọlu ère náà àtẹ́lẹsẹ̀ irin àti amọ̀, ó fọ́ wọn wẹ́wẹ́. 35 Nígbà náà ni irin, amọ̀, idẹ, fàdákà àti wúrà fọ́ wẹ́wẹ́ lẹ́sẹ̀kan náà, ó dàbí ìyàngbò a fẹ́ kúrò lórí ọkà àsìkò ̀̀rùn. Afẹ́fẹ́ gbé gbogbo rẹ̀ lọ láìṣẹ́ku ̀kan mọ́, òkúta ó fọ́ ère náà di òkè ńlá, ó gba gbogbo ayé.

36 "Èyí ni àlá náà, nígbà yìí ni a ó sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún ọba. 37 Ìwọ ọba jẹ́ ọba àwọn ọba. Ọlọ́run ̀run ti fi ìjọba agbára, títóbi àti ògo fún ; 38 ọwọ́ rẹ fi gbogbo ènìyàn, àwọn ẹranko igbó àti ẹyẹ ojú ̀run . ibi gbogbo wọ́n ń gbé, ó ti fi ́ ṣe olórí i wọn. Ìwọ ni orí wúrà náà.

39 "Lẹ́yìn èyí ni ìjọba mìíràn yóò dìde, lágbára tìrẹ, lẹ́yìn in rẹ̀, ìjọba kẹta yóò dàbí idẹ, èyí yóò jẹ ọba lórí i gbogbo ayé. 40 Ju gbogbo rẹ̀ lọ, ìjọba kẹrin yóò , ìjọba náà yóò lágbára irin, gẹ́gẹ́ irin ti í fọ́, ń lọ gbogbo nǹkan àti irin ti í fọ́ nǹkan wẹ́wẹ́, bẹ́̀ ni yóò fọ́ yóò lọ gbogbo àwọn tókù. 41 o ṣe i àtẹ́lẹsẹ̀ àti ọmọ ìka ẹsẹ̀ jẹ́ apá kan amọ̀ àti apá kan irin, bẹ́̀ ni ìjọba yóò ṣe pín; ṣùgbọ́n yóò agbára irin díẹ̀ nínú rẹ̀, ó ṣe i irin dàpọ̀ mọ́ amọ̀. 42 ọmọ ìka ẹsẹ̀ ṣe jẹ́ apá kan irin àti apá kan amọ̀, bẹ́̀ ni ìjọba yìí yóò lágbára lápákan lágbára lápákan. 43 Gẹ́gẹ́ o ti i irin dàpọ̀ mọ́ amọ̀, báyìí ni àwọn ènìyàn yóò ṣe dàpọ̀ mọ́ ara wọn ti ìgbéyàwó, ṣùgbọ́n wọn ìṣọ̀kan, irin ṣe dàpọ̀ mọ́ amọ̀.

44 "àsìkò àwọn ọba náà, Ọlọ́run ̀run yóò gbé ìjọba èyí le è bàjẹ́ kalẹ̀, èyí a fi ẹlòmíràn lọ́wọ́. Yóò run gbogbo ìjọba, yóò wọn òpin, ṣùgbọ́n ìjọba yìí yóò dúró láéláé." 45 Gẹ́gẹ́ o ṣe i a òkúta láti ara òkè, láì ti ọwọ́ ẹnikẹ́ni , òkúta èyí ó fọ́ irin, idẹ, amọ̀, fàdákà àti wúrà wẹ́wẹ́.

"Ọlọ́run ó tóbi ti fihan ọba, ohun yóò ṣẹlẹ̀ ọjọ́ iwájú. Òtítọ́ ni àlá náà, bẹ́̀ ni ìtumọ̀ rẹ̀ ṣe é gbẹ́kẹ̀."

46 Nígbà náà, ni Nebukadnessari ọba dojúbolẹ̀ níwájú u Daniẹli ó fi orí balẹ̀ fún un, ó pàṣẹ wọn ó mu ọrẹ àti òórùn tùràrí fún Daniẹli. 47 Ọba fún Daniẹli , "Dájúdájú Ọlọ́run rẹ ni Ọlọ́run àwọn ọlọ́run àti Olúwa àwọn ọba gbogbo àti olùfihàn àwọn àṣírí, nítorí ìwọ fi àṣírí yìí hàn."

48 Nígbà náà ni ọba gbé Daniẹli ga, ó fún un ̀bùn ńlá ó pọ̀. Ó fi ṣe olórí i gbogbo agbègbè ìjọba Babeli àti olórí gbogbo àwọn amòye Babeli. 49 Daniẹli béèrè lọ́wọ́ ọba, ó yan Ṣadraki, Meṣaki, àti Abednego gẹ́gẹ́ alábojútó ìgbèríko Babeli ṣùgbọ́n Daniẹli fúnra rẹ̀ ààfin ọba.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-