Publicidade

Daniel 7

Daniẹli àlá ẹranko mẹ́rin

1 ọdún àkọ́kọ́ Belṣassari ọba Babeli, Daniẹli àlá kan, ìran náà ọkàn an rẹ̀ ó ṣe sùn sórí ibùsùn un rẹ̀, ó kọ àlá náà sílẹ̀.

2 Daniẹli sọ , "Nínú ìran mi lóru mo ó, mo afẹ́fẹ́ ̀run mẹ́rin ó ń ru omi Òkun ńlá sókè. 3 7.3: If 13.1.7.3,7,21: If 11.7.Ẹranko ńlá mẹ́rin ó yàtọ̀ ara wọn, jáde láti inú Òkun náà.

4 7.4-6: If 13.2. "Ẹranko kìn-ín-ní dàbí i kìnnìún, ó ìyẹ́ apá a idì, mo títí a fi fa ìyẹ́ apá rẹ̀ náà tu, a gbé e sókè kúrò ilẹ̀, a ó fi ẹsẹ̀ dúró ènìyàn, a fi àyà ènìyàn fún un.

5 "Mo tún ẹranko kejì, ó irú ẹranko ńlá beari kan ó ń gbé ilẹ̀ òtútù; o gbé ara sókè apá kan, ó egungun ìhà mẹ́ta láàrín ̀yìn in rẹ̀, wọ́n sọ fún un , Dìde o jẹ ẹran pọ̀!’

6 "Lẹ́yìn ìgbà náà, mo tún ẹranko kẹta ó àmọ̀tẹ́kùn. Ẹranko náà ìyẹ́ i ti ẹyẹ ̀yìn, ó orí mẹ́rin, a fún un agbára láti ṣe ìjọba.

7 7.7: If 12.3; 13.1; 17.3. "Lẹ́yìn èyí, nínú ìran mi òru mo tún ẹranko kẹrin, ó dẹ́rùbà ni, ó dáyà fo ni, ó lágbára gidigidi. Ó eyín irin ńlá; ó ń jẹ, ó ń fọ́ túútúú, ó fi ẹsẹ̀ tẹ èyí tókù mọ́lẹ̀. Ó yàtọ̀ gbogbo àwọn ẹranko ti ìṣáájú, ó ìwo mẹ́wàá.

8 7.8,11: If 13.5. "mo ṣe ń ronú nípa ìwo náà, nígbà náà ni mo ìwo mìíràn, ó kéré ó jáde àárín wọn; mẹ́ta lára àwọn ìwo ti àkọ́kọ́ fàtu níwájú u rẹ̀. Ìwo yìí ojú i ojú ènìyàn àti ẹnu ń sọ̀rọ̀ ìgbéraga.

Ìdájọ́ níwájú ẹni ìgbàanì

9 7.9: If 1.14; 20.4,11. "mo ṣe ń ,

"a gbé ìtẹ́ ọba kan kalẹ̀,

ẹni ìgbàanì jókòó sórí ìtẹ́ rẹ̀.

Aṣọ rẹ̀ funfun ̀gbọ̀n òwú;

irun orí rẹ̀ funfun òwú,

ìtẹ́ ọba rẹ̀ ọwọ́ iná.

Àwọn kẹ̀kẹ́ rẹ ń i iná.

10 7.10: If 5.11; 20.12. Odò iná ń sàn,

ó ń jáde iwájú rẹ̀ .

Àwọn ẹgbẹ̀rún lọ́ẹgbẹ̀rún ń ṣe ìránṣẹ́ fún un;

̀ẹgbẹẹgbàárùn-ún nígbà ẹgbàárùn-ún dúró níwájú rẹ̀.

Àwọn onídàájọ́ jókòó,

a ṣí ìwé wọ̀n-ọn-nì sílẹ̀.

11 "Nígbà náà ni mo bẹ̀rẹ̀ , nítorí àwọn ̀rọ̀ ìgbéraga ìwo náà ń sọ, mo títí a fi pa ẹranko náà, a pa á run, a ú sínú iná ń . 12 A gba ìjọba lọ́wọ́ àwọn ẹranko yòókù, ṣùgbọ́n a fún wọn láààyè láti fún ìgbà díẹ̀.

13 7.13-14: Mt 24.30; 26.64; Mk 13.26; 14.62; Lk 21.27; 22.69; If 1.7,13; 14.14. "Nínú ìran mi òru mo , mo ẹnìkan ó dúró iwájú u mi, ó ọmọ ènìyàn, ó ń bọ̀ nínú àwọsánmọ̀ ̀run, ó ń bọ̀ ̀dọ̀ ẹni ìgbàanì, a u iwájú rẹ̀. 14 7.14,18,22,27: If 11.15.A fi ìjọba, ògo àti agbára ilẹ̀ ọba fún un; gbogbo ènìyàn, orílẹ̀-èdè àti èdè gbogbo wọn wólẹ̀ fún un. Ìjọba rẹ̀, ìjọba ayérayé ni, èyí le è kọjá, ìjọba rẹ̀ le è díbàjẹ́ láéláé.

15 "Ọkàn èmi Daniẹli, dàrú, ìran ó sọ́kàn mi dẹ́rùbà . 16 Mo lọ ̀kan nínú àwọn ó dúró níbẹ̀, mo bi í léèrè òtítọ́ ìtumọ̀ nǹkan wọ̀nyí.

"Ó sọ fún mi, ó túmọ̀ àwọn nǹkan wọ̀nyí fún mi: 17 Àwọn ẹranko ńlá mẹ́rin yìí, ni ìjọba mẹ́rin yóò dìde ayé. 18 Ṣùgbọ́n, ẹni mímọ́ ti ̀gá-ògo ni yóò gba ìjọba náà, yóò jogún un rẹ títí láé àti títí láéláé.

19 "Nígbà náà, ni mo fẹ́ mọ ìtumọ̀ òtítọ́ ẹranko kẹrin, ó yàtọ̀ àwọn yòókù, èyí ó dẹ́rùba ni gidigidi, ó eyín irin àti èékánná idẹ, ẹranko ó ń run ó ń pajẹ, ó ń fi ẹsẹ̀ tẹ èyí tókù mọ́lẹ̀. 20 7.20,24: If 17.12.Bẹ́̀ ni mo fẹ́ mọ̀ nípa ìwo mẹ́wàá orí rẹ̀ àti nípa ìwo yòókù ó jáde, nínú èyí mẹ́ta lára wọn ṣubú, ìwo ó ojú, ẹnu rẹ̀ ń sọ̀rọ̀ ìgbéraga. 21 7.21: If 13.7.mo ṣe ń , ìwo yìí ń àwọn ènìyàn mímọ́ jagun, ó borí i wọn, 22 títí ẹni ìgbàanì fi , ó ṣe ìdájọ́ ìdáláre fún àwọn ẹni mímọ́ ̀gá-ògo, àsìkò náà nígbà àwọn ẹni mímọ́ náà jogún ìjọba.

23 "Ó ṣe àlàyé yìí fún mi , Ẹranko kẹrin ni ìjọba kẹrin yóò ayé. Yóò yàtọ̀ gbogbo àwọn ìjọba yòókù yóò pa gbogbo ayé run, yóò tẹ̀ ́ mọ́lẹ̀, yóò fọ́ ́ wẹ́wẹ́. 24 Ìwo mẹ́wàá ni ọba mẹ́wàá yóò láti inú ìjọba yìí. Lẹ́yìn wọn ọba mìíràn yóò dìde, ti yóò yàtọ̀ àwọn ti ìṣáájú, yóò borí ọba mẹ́ta. 25 7.25: If 12.14.Yóò sọ̀rọ̀ odi ̀gá-ògo, yóò pọ́n ẹni mímọ́ lójú, yóò gbèrò láti ìgbà àti òfin padà. A ó fi àwọn ẹni mímọ́ e lọ́wọ́ fún ìgbà díẹ̀, ọdún méjì àti ààbọ̀.

26 " Ṣùgbọ́n àwọn onídàájọ́ yóò jókòó, nígbà náà ni a ó gba agbára rẹ̀, a ó pa á rùn pátápátá títí ayé. 27 Nígbà náà, ni a ó gba ìjọba, agbára àti títóbi ìjọba rẹ̀ abẹ́ gbogbo ̀run, a ó fi fún àwọn ẹni mímọ́, àwọn ènìyàn ̀gá-ògo. Ìjọba rẹ̀ yóò jẹ́ ìjọba títí ayé, gbogbo aláṣẹ ni yóò máa ṣe ìgbọ́ràn i, wọn yóò máa sìn ín.

28 "Báyìí ni àlá náà ṣe parí, ọkàn èmi Daniẹli dàrú gidigidi, nítorí èrò ọkàn mi yìí, ojú mi yípadà ṣùgbọ́n mo pa ̀ràn náà mọ́ ọkàn mi."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-