Publicidade

Eclesiastes 1

Asán ni ohun ayé

1 ̀rọ̀ Oniwaasu, ọmọ Dafidi, ọba Jerusalẹmu:

2 "Asán inú asán!"

Oníwàásù náà ,

"Asán inú asán!

Gbogbo rẹ̀ asán ni."

3 ni ènìyàn jẹ èrè lórí gbogbo iṣẹ́ rẹ̀,

lórí èyí ó ń ṣe wàhálà lábẹ́ oòrùn?

4 ìran kan ti ni ìran mìíràn ń kọjá lọ,

síbẹ̀ ayé dúró títí láé.

5 Oòrùn ń ràn, oòrùn ń wọ̀,

ó sáré padà ibi ó ti yọ.

6 Afẹ́fẹ́ ń fẹ́ lọ ìhà gúúsù,

Ó ń fẹ́ yípo ìhà àríwá,

a tún padà ̀rẹ̀.

7 Gbogbo odò ń sàn inú Òkun,

síbẹ̀síbẹ̀ Òkun kún.

Níbi àwọn odò ti ,

níbẹ̀ ni wọ́n tún padà .

8 Ohun gbogbo ni ó ń àárẹ̀ ,

ju èyí ẹnu le è sọ.

Ojú ì ìrírí ó tẹ́ lọ́rùn,

bẹ́̀ ni, etí ì kún fún gbígbọ́.

9 Ohun ó ti tẹ́lẹ̀ náà ni yóò máa , ohun a ti ṣe sẹ́yìn

òun ni a ó tún máa ṣe padà

ohun tuntun lábẹ́ oòrùn.

10 Ǹjẹ́ ohun kan ẹnìkan le è sọ ,

"ó! Ohun tuntun ni èyí"?

Ó ti tẹ́lẹ̀ ọjọ́ ti pẹ́,

o ti ṣáájú tiwa.

11 ìrántí ohun ìṣáájú

bẹ́̀ ni ìrántí yóò fún

ohun ìkẹyìn ń bọ̀

lọ́dọ̀ àwọn ń bọ̀ ìgbà ìkẹyìn.

Asán ni ọgbọ́n ènìyàn

12 Èmi, Oniwaasu ti jẹ ọba lórí Israẹli Jerusalẹmu . 13 Mo fi àsìkò mi sílẹ̀ láti kọ́ àti láti ṣe àwárí pẹ̀ọgbọ́n, gbogbo ohun ó ń ṣẹlẹ̀ lábẹ́ ̀run. Háà! Ẹrù wúwo Ọlọ́run ti gbé àwọn ènìyàn. 14 Èmi ti ohun gbogbo ó ń ṣẹlẹ̀ lábẹ́ oòrùn, gbogbo rẹ̀ ìtumọ̀ ẹní gbìyànjú àti afẹ́fẹ́ ni.

15 Ohun ó ti wọ́ le è ṣe é tọ́ mọ́,

ohun le è ṣe é .

16 Mo nínú ara mi, "ó, mo ti dàgbà, ọgbọ́n mi ti pọ̀ ju ti ẹnikẹ́ni ó ti ṣe alákòóso Jerusalẹmu síwájú mi lọ, mo ti ìrírí púpọ̀ nípa ọgbọ́n àti ìmọ̀." 17 Nígbà náà ni mo fi ara láti ìmọ̀ nípa ọgbọ́n, àti pàápàá àìgbọ́n àti òmùgọ̀, ṣùgbọ́n mo , èyí pẹ̀ẹni ń gbìyànjú àti afẹ́fẹ́ ni.

18 Nítorí ọgbọ́n púpọ̀ ìbànújẹ́ púpọ̀ ń ,

ìmọ̀ ṣe pọ̀ náà ni ìbànújẹ́ ń pọ̀ .

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-