Publicidade

Eclesiastes 9

Àyànmọ́ kan náà fún gbogbo wọn

1 Nígbà náà ni mo ronú lórí gbogbo èyí, mo parí rẹ̀ , olóòtọ́ àti ọlọ́gbọ́n àti ohun wọ́n ń ṣe ọwọ́ Ọlọ́run, ṣùgbọ́n ènìyàn ó mọ̀ bóyá ìfẹ́ tàbí ìríra ni ó ń dúró de òun. 2 Àyànmọ́ kan náà ni gbogbo wọn yànolóòtọ́ àti ènìyàn búburú, rere àti ibi, mímọ́ àti àìmọ́, àwọn ó ń ẹbọ àti àwọn ẹbọ.

ó ti pẹ̀ènìyàn rere

bẹ́̀ náà ni ó pẹ̀ẹni dẹ́ṣẹ̀

ó ti pẹ̀àwọn ó ń ṣe ìbúra

bẹ́̀ náà ni ó pẹ̀àwọn ó ń bẹ̀láti ṣe ìbúra.

3 Ohun búburú ni èyí jẹ́ nínú gbogbo ohun ó ń ṣẹlẹ̀ lábẹ́ oòrùn. Ìpín kan ṣoṣo ni ó ń dúró de gbogbo wọn, ọkàn ènìyàn pẹ̀kún fún ibi, ìsínwín ọkàn wọn nígbà wọ́n láààyè àti nígbà wọ́n darapọ̀ mọ́ òkú. 4 Ẹnikẹ́ni ó láàrín alààyè ìrètíkódà ààyè ajá sàn dáradára ju òkú kìnnìún lọ!

5 Nítorí ẹni ó láààyè mọ̀ àwọn yóò

ṣùgbọ́n òkú mọ ohun kan

wọn èrè kankan mọ́,

àti kódà ìrántí wọn di ohun ìgbàgbé.

6 Ìfẹ́ wọn, ìríra wọn,

àti ìlara wọn ti parẹ́:

láéláé kọ́ ni wọn yóò tún ìpín

nínú ohunkóhun ó ń ṣẹlẹ̀ lábẹ́ oòrùn.

7 Lọ jẹ oúnjẹ rẹ pẹ̀ayọ̀, o mu ọtí wáìnì rẹ pẹ̀inú dídùn ọkàn, nítorí ìsinsin yìí ni Ọlọ́run síjú àánú wo ohun o ṣe. 8 Máa wọ aṣọ funfun nígbàkígbà o máa fi òróró yan orí rẹ nígbà gbogbo. 9 Máa jẹ ayé pẹ̀ìyàwó rẹ, ẹni o fẹ́ràn, gbogbo ọjọ́ ayé àìní ìtumọ̀ Ọlọ́run ti fi fún lábẹ́ oòrùngbogbo ọjọ́ àìní ìtumọ̀ rẹ. Nítorí èyí ni ìpín tìrẹ ayé àti nínú iṣẹ́ wàhálà rẹ abẹ́ oòrùn. 10 Ohunkóhun ọwọ́ rẹ láti ṣe, ṣe é pẹ̀gbogbo agbára rẹ, nítorí iṣẹ́ ṣíṣe tàbí ìpinnu tàbí ìmọ̀ tàbí ọgbọ́n nínú isà òkú níbi ò ń lọ.

11 Mo ti ohun mìíràn lábẹ́ oòrùn.

Eré ìje í ṣe fún ẹni ó yára

tàbí ogun fún alágbára,

bẹ́̀ ni oúnjẹ fún ọlọ́gbọ́n

tàbí ọrọ̀ fún ẹni ó òye

tàbí ojúrere fún ẹni ó ìmọ̀;

ṣùgbọ́n ìgbà àti èsì ń ṣẹlẹ̀ gbogbo wọn.

12 Síwájú i, ẹni ó mọ ìgbà àkókò rẹ̀ yóò ,

gẹ́gẹ́ a ti ń ẹja nínú àwọ̀n búburú

tàbí a ń ẹyẹ nínú okùn

gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni a ń ènìyàn àkókò ibi

ó ṣubú wọ́n láìròtẹ́lẹ̀.

Ọgbọ́n dára ju òmùgọ̀ lọ

13 Mo tún àpẹẹrẹ ọgbọ́n ó dùn mọ́ mi lábẹ́ oòrùn. 14 Ìlú kékeré kan ènìyàn díẹ̀ nínú rẹ̀ ìgbà kan . Ọba alágbára kan ṣígun tọ ìlú náà lọ, ó i po, ó kọ́ ilé ìṣọ́ ó tóbi lòdì i. 15 Ṣùgbọ́n, tálákà ọkùnrin ó jẹ́ ọlọ́gbọ́n kan ń gbé ìlú náà, ó gba gbogbo ìlú u rẹ̀ pẹ̀ọgbọ́n rẹ̀. Ṣùgbọ́n ẹni ó rántí ọkùnrin tálákà náà. 16 Nítorí náà mo sọ , "Ọgbọ́n dára ju agbára." Ṣùgbọ́n a kẹ́gàn ọgbọ́n ọkùnrin tálákà náà, wọn ̀rọ̀ rẹ̀ ṣe.

17 ̀rọ̀ pẹ̀lẹ́ ọlọ́gbọ́n ènìyàn a máa ìmúṣẹ

ju igbe òmùgọ̀ alákòóso lọ.

18 Ọgbọ́n dára ju ohun èlò ogun lọ,

ṣùgbọ́n ẹnìkan dẹ́ṣẹ̀ a máa ba ohun dídára púpọ̀ jẹ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-