Publicidade

Hebreus 10

Ìrúbọ Kristi lẹ́̀kan ṣoṣo fún gbogbo ènìyàn

1 Nítorí òfin jẹ́ òjìji àwọn ohun rere ti ń bọ̀ í ṣe àwòrán tòótọ́ fún àwọn òtítọ́ náà, wọn fi ẹbọ kan náà wọn ń nígbà gbogbo lọ́dọọdún mu àwọn ń jọ́sìn di pípé. 2 ṣe bẹ́̀, a ìbá dẹ́kun àti máa wọn, nítorí àwọn ti ń sìn ki ìbá ìmọ̀ ̀ṣẹ̀, nígbà a ti wẹ̀ wọ́n mọ́ lẹ́̀kan ṣoṣo. 3 Ṣùgbọ́n nínú ẹbọ wọ̀nyí ni a ń ṣe ìrántí ̀ṣẹ̀ lọ́dọọdún. 4 Nítorí ko ṣe é ṣe fún ̀jẹ̀ akọ màlúù àti ti ewúrẹ́ láti ̀ṣẹ̀ kúrò.

5 Nítorí náà nígbà Kristi ayé, ó ,

"Ìwọ fẹ́ ẹbọ àti ọrẹ,

ṣùgbọ́n ara ni ìwọ ti pèsè fún mi,

6 ẹbọ sísun àti ẹbọ fún ̀ṣẹ̀ ni

ìwọ inú dídùn .

7 Nígbà náà ni mo , Kíyèsi i (nínú ìwé kíká ni a gbé kọ ́ nípa ti èmi)

mo láti ṣe ìfẹ́ rẹ, Ọlọ́run.’ "

8 Nígbà o ni ìṣáájú , "Ìwọ fẹ́ ẹbọ àti ọrẹ àti ẹbọ sísun, àti ẹbọ fún ̀ṣẹ̀, bẹ́̀ ni ìwọ ni inú dídùn si wọn" (àwọn èyí a ń gẹ́gẹ́ òfin). 9 Nígbà náà ni ó , "Kíyèsi i, mo de láti ṣe ìfẹ́ rẹ Ọlọ́run." Ó ti ìṣáájú kúrò, a fi ìdí èkejì múlẹ̀. 10 Nípa ìfẹ́ náà ni a ti sọ di mímọ́ nípa ẹbọ ti Jesu Kristi fi ara rẹ̀ lẹ́̀kan ṣoṣo.

11 Àti olúkúlùkù àlùfáà ń dúró lójoojúmọ́ láti ṣiṣẹ́ ìsìn, ó ń ṣe ẹbọ kan náà nígbàkígbà, ̀ṣẹ̀ kúrò láé. 12 Ṣùgbọ́n òun, lẹ́yìn ìgbà o ti ẹbọ kan fún ̀ṣẹ̀ títí láé, o jókòó lọ́wọ́ ̀tún Ọlọ́run; 13 láti ìgbà náà, ó retí títí a o fi àwọn ̀rẹ̀ ṣe àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀. 14 Nítorí nípa ẹbọ kan a ti àwọn a sọ di mímọ́ títí láé.

15 ̀Mímọ́ ń jẹ́rìí fún wa pẹ̀, nítorí lẹ́yìn ó ,

16 "Èyí ni májẹ̀ti èmi o ba wọn

lẹ́hìn àwọn ọjọ́ wọ̀nyí, ni Olúwa .

Èmi o fi òfin mi wọn ọkàn,

inú wọn pẹ̀ni èmi o kọ wọn ."

17 Ó tún sọ :

"̀ṣẹ̀ wọn àti àìṣedéédéé wọn

lèmi yóò rántí mọ́."

18 Ṣùgbọ́n níbi ìmúkúrò ìwọ̀nyí gbé , ìrúbọ fún ̀ṣẹ̀ mọ́.

Ìpè ìforítì

19 Ará, ǹjẹ́ a ti ìgboyà láti wọ inú Ibi Mímọ́ Jùlọ nípasẹ̀ ̀jẹ̀ Jesu, 20 nípa ̀títún àti ààyè, o mímọ́ fún wa, àti láti kọjá aṣọ ìkélé èyí yìí , ara rẹ̀; 21 àti a ti ni àlùfáà gíga lórí ilé Ọlọ́run; 22 jẹ́ a fi òtítọ́ ọkàn súnmọ́ tòsí ni ̀kún ìgbàgbọ́, a wẹ ọkàn wa mọ́ kúrò nínú ̀ọkàn búburú, a fi omi mímọ́ wẹ ara wa . 23 jẹ́ a di ìjẹ́wọ́ ìrètí wa mu ṣinṣin ni àìṣiyèméjì, nítorí olóòtítọ́ ẹni o ṣe ìlérí. 24 jẹ́ a yẹ ara wa láti ru ara wa ìfẹ́ àti iṣẹ́ rere, 25 a ma máa kọ ìpéjọpọ̀ ara wa sílẹ̀, gẹ́gẹ́ bi àṣà àwọn ẹlòmíràn; ṣùgbọ́n a máa gba ara ẹni níyànjú pẹ̀lúpẹ̀̀yin ti i ọjọ́ náà ń súnmọ́ etílé.

26 Nítorí àwa ba mọ̀ ́n mọ̀ dẹ́ṣẹ̀ lẹ́yìn ìgbà àwa ti gba ìmọ̀ òtítọ́ tún ẹbọ fún ̀ṣẹ̀ mọ́. 27 ṣe ìrètí ìdájọ́ ó ba ni lẹ́, àti ti ìbínú ti o múná, yóò pa àwọn ̀run. 28 Ẹnikẹ́ni ó ba gan òfin Mose, ó láìsí àánú nípa ̀ẹni méjì tàbí mẹ́ta. 29 Mélòó mélòó ni a o jẹ ẹni náà ìyà kíkan, ẹni o tẹ Ọmọ Ọlọ́run mọ́lẹ̀ ó ti ka ̀jẹ̀ májẹ̀ti a fi sọ ́ di mímọ́ si ohun àìmọ́, ó ti kẹ́gàn ̀oore-ọ̀fẹ́. 30 Nítorí àwa mọ ẹni o , ̀san ni ti èmi, Olúwa , "Èmi ó gbẹ̀san." Àti pẹ̀, "Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀." 31 Ohun ̀ni láti ṣubú ọwọ́ Ọlọ́run alààyè.

32 Ṣùgbọ́n rántí ọjọ́ ìṣáájú nínú èyí , nígbà a ti yin lójú, fi ara da wàhálà ńlá ti ìjìyà; 33 lápákan, nígbà a sọ yín di ìran wíwò nípa ̀gàn àti ìpọ́njú; àti lápákan, nígbà ̀yin di ẹgbẹ́ àwọn a ṣe bẹ́̀ si. 34 Nítorí ̀yin àwọn ó nínú ìdè kẹ́dùn, fi ayọ̀ gba ìkólọ ẹrù yin, nítorí ̀yin mọ nínú ara yin , ni ọrọ̀ ó títí, ó dára bẹ́̀ lọ. 35 Nítorí náà ṣe gbé ìgboyà yín sọnù, èyí ti o ni èrè ńlá.

36 Nítorí ̀yin le ṣe aláìní sùúrù, nítorí ìgbà ̀yin ti ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run tan ̀yin le gba ìlérí náà. 37 Nítorí,

"Ni ìwọ̀n ìgbà díẹ̀ i,

ẹni náà ti ń bọ̀ yóò ,

yóò jáfara.

38 Ṣùgbọ́n,

"Olódodo ni yóò nípa ìgbàgbọ́.

Ṣùgbọ́n o ba fàsẹ́yìn,

ọkàn mi inú dídùn i."

39 Ṣùgbọ́n àwa nínú àwọn ń fàsẹ́yìn sínú ègbé; ṣe nínú àwọn o gbàgbọ́ ìgbàlà ọkàn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-