Publicidade

Hebreus 11

Nípa ìgbàgbọ́

1 Ǹjẹ́ ìgbàgbọ́ ìdánilójú ohun o ń retí, ìjẹ́rìí ohun a . 2 Nítorí nínú rẹ ni àwọn alàgbà àtijọ́ ̀rere.

3 Nípa ìgbàgbọ́ ni a mọ̀ a ti ayé nípa ̀rọ̀ Ọlọ́run; nítorí náà í ṣe ohun o hàn ni a fi ohun a ń ri.

4 11.4: Gẹ 4.3-10. Nípa ìgbàgbọ́ Abeli ẹbọ Ọlọ́run ó sàn ju ti Kaini lọ, nípa èyí a jẹ́rìí rẹ̀ pe olódodo ni, Ọlọ́run ń jẹ́rìí ̀bùn rẹ̀, àti nípa rẹ̀ náà, o ti jẹ́ o ti , síbẹ̀ o ń fọhùn.

5 11.5: Gẹ 5.21-24. Nípa ìgbàgbọ́ ni a ṣí Enoku ipò padà o ṣe ikú; a i mọ́, nítorí Ọlọ́run ṣí i ipò padà ṣáájú ìṣípò padà rẹ̀, a jẹ́rìí yìí i o wu Ọlọ́run. 6 Ṣùgbọ́n láìsí ìgbàgbọ́ ṣe é ṣe láti ú; nítorí ẹni ó ń tọ Ọlọ́run ṣàì gbàgbọ́ ó ń bẹ, àti òun olùṣẹ̀san fún àwọn o fi ara balẹ̀ a.

7 11.7: Gẹ 6.13-22. Nípa ìgbàgbọ́ ni Noa, nígbà ti Ọlọ́run, kìlọ̀ ohun a kóò ì fún un, o bẹ̀Ọlọ́run ó kan ọkọ̀ fún ìgbàlà ilé rẹ̀, nípa èyí ó da ayé lẹ́bi, ó di ajogún òdodo i ṣe nípa ìgbàgbọ́.

8 11.8-9: Gẹ 12.1-8. Nípa ìgbàgbọ́ Abrahamu, nígbà a ti e láti jáde lọ ibi òun yóò gbà fún ilẹ̀ ìní, ó gbọ́, ó jáde lọ, láì mọ ibi òun ń . 9 Nípa ìgbàgbọ́ o ṣe àtìpó ilẹ̀ ìlérí, ẹni ni ilẹ̀ àjèjì, o ń gbé inú àgọ́, pẹ̀Isaaki àti Jakọbu, àwọn ajogún ìlérí kan náà pẹ̀rẹ̀, 10 nítorí ó ń retí ìlú ó ìpìlẹ̀; èyí Ọlọ́run tẹ̀ó kọ́. 11 11.11: Gẹ 17.19; 18.11-14; 21.2.Nípa ìgbàgbọ́ ni Sara tìkára rẹ̀ pẹ̀fi gba agbára láti lóyún, nígbà ó kọjá ìgbà rẹ̀, nítorí o ka ẹni o ṣe ìlérí olóòótọ́. 12 11.12: Gẹ 15.5-6; 22.17; 32.12.Nítorí náà ni ̀pọ̀lọpọ̀ ṣe ti ara ọkùnrin kan jáde, àní ara ẹni o dàbí òkú, ọmọ ìràwọ̀ ojú ̀run lọ́pọ̀lọ́pọ̀, àti iyanrìn etí Òkun láìníye.

13 11.13: Sm 39.12; Gẹ 23.4. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ó nínú ìgbàgbọ́, láìrí àwọn ìlérí náà gbà, ṣùgbọ́n wọn wọn ni òkèrè réré, wọ́n gbá wọn , wọ́n jẹ́wọ́ àlejò àti àjèjì ni àwọn lórí ilẹ̀ ayé. 14 Nítorí àwọn o ń sọ irú ohun bẹ́̀ fihàn gbangba , wọn ń ṣe àfẹ́ìlú kan i ṣe tiwọn. 15 Àti nítòótọ́, ìbá ṣe wọ́n fi ìlú tiwọn jáde ọkàn, wọn ìbá ti ààyè padà. 16 11.16: El 3.6,15; 4.5.Ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n ń fẹ́ ìlú kan o dára bẹ́̀ lọ, èyí yìí ni ti ̀run, nítorí náà ojú wọn ti Ọlọ́run, a máa òun ni Ọlọ́run wọn; nítorí o ti pèsè ìlú kan sílẹ̀ fún wọn.

17 11.17: Gẹ 22.1-10. Nípa ìgbàgbọ́ ni Abrahamu, nígbà a dán an láti, fi Isaaki ẹbọ: àní òun ẹni ó ìlérí gba múra tan láti fi ọmọ bíbí rẹ kan ṣoṣo ẹbọ. 18 11.18: Gẹ 21.12.Nípa ẹni , "Nínú Isaaki ni a ó ti pe irú-ọmọ rẹ̀." 19 Ó ó si Ọlọ́run tilẹ̀ gbé e dìde kúrò nínú òkú, bẹ́̀ ni, a sọ ́ lọ́àpẹẹrẹ, ó gbà á padà.

20 11.20: Gẹ 27.27-29,39-40. Nípa ìgbàgbọ́ Isaaki súre fún Jakọbu àti Esau ti ohun ń bọ̀.

21 11.21: Gẹ 48; 47.31. Nípa ìgbàgbọ́ ni Jakọbu, nígbà o ń ku lọ, ó súre fún àwọn ọmọ Josẹfu ni ̀kọ̀̀kan; ó sinmi ìtẹríba orí ̀rẹ̀.

22 11.22: Gẹ 50.24-25; Ek 13.19. Nípa ìgbàgbọ́ ni Josẹfu, nígbà ó ń ku lọ, ó rántí ìjáde lọ àwọn ọmọ Israẹli; ó pàṣẹ ti àwọn egungun rẹ̀.

23 11.23: Ek 2.2; 1.22. Nípa ìgbàgbọ́ àwọn òbí Mose pa a mọ́ fún oṣù mẹ́ta nígbà a i, nítorí tiwọn i arẹwà ọmọ; wọn bẹ̀àṣẹ ọba.

24 11.24: Ek 2.10,11-15. Nípa ìgbàgbọ́ ni Mose, nígbà o dàgbà, ó kọ̀ ki a máa òun ni ọmọ ọmọbìnrin Farao; 25 o kúkú yàn láti máa ba àwọn ènìyàn Ọlọ́run jìyà, ju jíjẹ fàájì ̀ṣẹ̀ fún ìgbà díẹ̀. 26 Ó ka ̀gàn Kristi si ọrọ̀ ó pọ̀àwọn ìṣúra Ejibiti lọ, nítorí ó ń wo èrè náà. 27 11.27: Ek 2.15.Nípa ìgbàgbọ́ ni o kọ Ejibiti sílẹ̀ láìbẹ̀ìbínú ọba: nítorí o dúró ṣinṣin ẹni ó n ri ẹni àìrí. 28 11.28: Ek 12.21-28,29-30.Nípa ìgbàgbọ́ ni ó da àsè ìrékọjá sílẹ̀, àti ìbùwọ́n ̀jẹ̀, ẹni ń pa àwọn àkọ́ọmọ a fi ọwọ́ kan wọn.

29 11.29: Ek 14.21-31. Nípa ìgbàgbọ́ ni wọn la òkun pupa kọjá bi ẹni ni ìyàngbẹ ilẹ̀ ni: ti àwọn ara Ejibiti dánwò, wọ́n ri.

30 11.30: Jo 6.12-21. Nípa ìgbàgbọ́ ni àwọn odi Jeriko wo lulẹ̀, lẹ́yìn ìgbà a wọn ni ọjọ́ méje.

31 11.31: Jo 2.1-21; 6.22-25. Nípa ìgbàgbọ́ ni Rahabu panṣágà ṣègbé pẹ̀àwọn gbọ́rọ̀ nígbà o tẹ́wọ́gbà àwọn àmì àlàáfíà.

32 11.32: On 6–8; 4–5; 13–16; 11–12; 1Sa 16–30; 2Sa 1–24; 1Ọb 1.1–2.11; 1Sa 1–12; 15.1–16.13. Èwo ni èmi o tún máa i? Nítorí ìgbà yóò kùnà fún mi láti sọ ti Gideoni, àti Baraki, àti Samsoni, àti Jefta; àti Dafidi, àti Samuẹli, àti ti àwọn wòlíì, 33 11.33: Da 6.àwọn ẹni nípasẹ̀ ìgbàgbọ́ tiwọn ṣẹ́gun ilẹ̀ ọba, wọn ṣiṣẹ́ òdodo, tiwọn gba ìlérí, tiwọn àwọn kìnnìún lénu, 34 11.34: Da 3.wọ́n pa agbára iná, wọ́n bọ́ lọ́wọ́ ojú idà, a sọ di alágbára nínú àìlera, wọ́n akọni nínú ìjà, wọ́n ogun àwọn àjèjì . 35 11.35: 1Ọb 17.17-24; 2Ọb 4.25-37.Àwọn obìnrin ri òkú wọn gbà nípa àjíǹde: a da àwọn ẹlòmíràn lóró, wọ́n kọ̀ láti gba ìdásílẹ̀; wọn ba àjíǹde o dára gbà. 36 Àwọn ẹlòmíràn ìjìyà ̀sín, àti nínà, àti ju bẹ́̀ lọ, ti ìdè àti ti túbú. 37 A sọ wọ́n ni òkúta, a fi ayùn rẹ́ wọn méjì, a dán wọn a fi idà pa wọn, wọ́n rìn káàkiri nínú awọ àgùntàn àti nínú awọ ewúrẹ́; wọn di aláìní, olùpọ́njú, ẹni a ń da lóró; 38 àwọn ẹni ayé ko yẹ fún. Wọ́n ń kiri nínú aṣálẹ̀, àti lórí òkè, àti nínú ihò àti nínú abẹ́ ilẹ̀.

39 Gbogbo àwọn wọ̀nyí a jẹ́rìí rere nípa ìgbàgbọ́, wọn ìlérí náà gbà, 40 nítorí Ọlọ́run ti pèsè ohun ó dára sílẹ̀ fún wa, láìsí wa, a ṣe wọn .

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-