Pular para o conteúdo
Publicidade

Hebreus 12

Ìbáwí àwọn Ọmọ Ọlọ́run

1 Nítorí náà a ti fi ìkùùkuu àwọsánmọ̀ o kún fún àwọn ẹlẹ́rìí báyìí wa , jẹ́ a pa ohun ìdíwọ́ gbogbo apá kan, àti ̀ṣẹ̀ o rọrùn láti di mọ́ wa, a máa fi sùúrù súré ìje a gbé ka iwájú wa, 2 12.2: Sm 110.1.a máa wo Jesu Olùpilẹ̀ṣẹ̀ àti aláṣepé ìgbàgbọ́ wa; ẹni nítorí ayọ̀ a gbé ka iwájú rẹ, o faradà àgbélébùú láìka ìtìjú , ó jókòó lọ́wọ́ ̀tún ìtẹ́ Ọlọ́run. 3 Máa ro ti ẹni ó faradà irú ìsọ̀rọ̀-òdì yìí láti ̀dọ̀ àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ si ara rẹ̀, ba á rẹ̀wẹ̀ni ọkàn yín, àárẹ̀ si mu yín.

Veja também