Publicidade

Hebreus 2

Ìkìlọ̀ láti ṣe ìgbọ́ràn

1 Nítorí náà, ó yẹ àwa máa fi iyè àwọn nǹkan wọ̀n-ọn-nì gidigidi àwa ti gbọ́, a ba à gbá wa lọ kúrò nínú wọn nígbà kan. 2 Nítorí ̀rọ̀ a ẹnu àwọn angẹli sọ dúró ṣinṣin, àti olúkúlùkù ̀ṣẹ̀ òfin àti àìgbọ́ràn gba ìjìyà ó tọ́ i, 3 kín ni ohun náà ó wa lérò a bọ́ kúrò nínú ìjìyà a náání ìgbàlà ńlá yìí? Ìgbàlà Olúwa fúnra rẹ̀ kọ́kọ́ kéde, èyí a fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ fún wa láti ọwọ́ àwọn ó gbọ́ ̀rọ̀ náà lẹ́nu rẹ̀. 4 Ọlọ́run jẹ́rìí i nípa àwọn iṣẹ́ àmì àti ìyanu àti oríṣìíríṣìí iṣẹ́ agbára àti nípa ̀bùn ̀Mímọ́ a pín gẹ́gẹ́ ìfẹ́ rẹ̀.

Jesu arákùnrin rẹ̀

5 Nítorí , í ṣe abẹ́ ìṣàkóso àwọn angẹli ni ó fi ayé ń bọ̀, àwa ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ . 6 Ṣùgbọ́n ibìkan ẹnìkan jẹ́rìí

"ni ènìyàn ìwọ fi ń ṣe ìrántí rẹ̀,

tàbí ọmọ ènìyàn, ìwọ fi ń bẹ̀ ́ ?

7 Ìwọ a onírẹ̀lẹ̀ díẹ̀ ju àwọn angẹli lọ;

ìwọ fi ògo àti ọlá de e ni adé,

ìwọ fi í jẹ olórí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ,

8 Ìwọ fi ohun gbogbo sábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀."

ti fífi ohun gbogbo sábẹ́ rẹ̀, ṣùgbọ́n àwa ì ì ohun kan ó abẹ́ àkóso rẹ̀. Síbẹ̀ nísinsin yìí àwa ì ì ó fi ohun gbogbo sábẹ́ ìṣàkóso rẹ̀. 9 Ṣùgbọ́n àwa Jesu ẹni a rẹ̀ sílẹ̀ díẹ̀ ju àwọn angẹli lọ fún àkókò díẹ̀, àní Jesu, ẹni a fi ògo àti ọlá adé nítorí ìjìyà wa; ó tọ́ ikú fún olúkúlùkù ènìyàn nípa oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run.

10 Nítorí ó yẹ fún Ọlọ́run, nítorí nípasẹ̀ ẹni ohun gbogbo ṣẹ̀ , láti àwọn ọmọ púpọ̀ sínú ògo, láti ṣe balógun ìgbàlà wọn ni àṣepé nípa ìjìyà. 11 Nítorí àti ẹni ń sọ ni di mímọ́ àti àwọn a ń sọ di mímọ́, láti ̀dọ̀ ẹnìkan ṣoṣo ni gbogbo wọn ti , nítorí èyí ni ṣe tijú láti wọ́n ni arákùnrin. 12 Àti ,

"Èmi ó sọ̀rọ̀ orúkọ rẹ̀ fún àwọn ará mi,

ni àárín ìjọ ni èmi yóò kọrin ìyìn rẹ̀."

13 Àti pẹ̀,

"Èmi yóò gbẹ́kẹ̀ mi e."

Àti pẹ̀,

"Kíyèsi í, èmi rèé, èmi àti àwọn ọmọ Ọlọ́run fi fún mi."

14 Ǹjẹ́ ni ìwọ̀n àwọn ọmọ ṣe alábápín ará àti ̀jẹ̀, bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni òun pẹ̀ṣe alábápín nínú ohun kan náà; ó ti ipa ikú rẹ̀ pa ẹni ó agbára ikú run, èyí ni èṣù. 15 o gba gbogbo àwọn ó tìtorí ìbẹ̀ikú lábẹ́ ìdè lọ́jọ́ ayé wọn gbogbo kúrò lọ́wọ́ ìbẹ̀. 16 Nítorí , nítòótọ́, í ṣe àwọn angẹli ni ó ṣe ìrànlọ́wọ́ fún, ṣùgbọ́n àwọn irú-ọmọ Abrahamu ni ó ṣe ìrànlọ́wọ́ fún. 17 Nítorí náà, ó yẹ nínú ohun gbogbo ó dàbí àwọn ará rẹ̀, ó jẹ́ aláàánú àti olóòtítọ́ alábojútó Àlùfáà nínú ohun i ṣe ti Ọlọ́run, o ṣe ètùtù fún ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn. 18 Nítorí níwọ̀n òun tìkára rẹ̀ ti jìyà a ti dán an , òun agbára láti ran àwọn a ń dánwò lọ́wọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-