Publicidade

Hebreus 9

Ìsìn nínú àgọ́ ayé yìí

1 Bẹ́̀ ni májẹ̀àkọ́kọ́ ìlànà fún ìsìn àti ibi mímọ́ ti ayé yìí. 2 A gbé àgọ́ kan dìde. Nínú yàrá rẹ̀ àkọ́kọ́ ni a ti ̀fìtílà, tábìlì, àti àkàrà ìfihàn. Èyí a ń ibi mímọ́. 3 Àti lẹ́yìn aṣọ ìkélé kejì, òun ni àgọ́ à ń Ibi Mímọ́ Jùlọ; 4 ó àwo tùràrí wúrà, àti àpótí ̀a fi wúrà yíká, nínú èyí ìkòkò wúrà ó manna gbé , àti ̀Aaroni o rúdí, àti àwọn wàláà májẹ̀; 5 àti lórí àpótí ni àwọn kérúbù ògo ti i síji bo ìtẹ́ àánú; èyí a sọ̀rọ̀ rẹ̀ nísinsin yìí lọ́kọ̀̀kan.

6 Ǹjẹ́ nígbà a ti ṣe ètò nǹkan wọ̀nyí báyìí, àwọn àlùfáà a máa lọ nígbàkígbà sínú àgọ́ èkínní, wọn a máa ṣe iṣẹ́ ìsìn. 7 Ṣùgbọ́n sínú èkejì ni olórí àlùfáà nìkan máa ń lọ lẹ́̀kan ṣoṣo lọ́dún, fún ara rẹ̀, àti fún ìṣìnà àwọn ènìyàn. 8 ̀Mímọ́ ń tọ́ka èyí a ì ì ṣí ̀Ibi Mímọ́ Jùlọ sílẹ̀ níwọ̀n ìgbà àgọ́ èkínní dúró, 9 èyí i ṣe àpẹẹrẹ fún ìgbà ìsinsin yìí. Gẹ́gẹ́ ètò yìí, a ń ̀bùn àti ẹbọ , ̀ọkàn olùsìn di pípé. 10 Èyí nínú ohun jíjẹ àti ohun mímu àti onírúurú ìwẹ̀, í ṣe ìlànà ti ara nìkan a fi lélẹ̀ títí fi di ìgbà àtúnṣe.

̀jẹ̀ ti Kristi

11 Ṣùgbọ́n nígbà Kristi olórí àlùfáà àwọn ohun rere ń bọ̀, nípasẹ̀ àgọ́ o tóbi ti ó ju ti ìṣáájú, èyí a fi ọwọ́ , èyí yìí ni, í ṣe ti ̀yìí. 12 Bẹ́̀ ni í ṣe nípasẹ̀ ̀jẹ̀ ewúrẹ́ àti ọmọ màlúù, ṣùgbọ́n nípa ̀jẹ̀ òun tìkára rẹ̀, o wọ Ibi Mímọ́ Jùlọ lẹ́̀kan ṣoṣo, lẹ́yìn ó ti ìdáǹdè àìnípẹ̀kun gbà fún wa. 13 Nítorí ̀jẹ̀ ewúrẹ́ àti ti akọ màlúù àti eérú ẹgbọrọ abo màlúù a fi wọ́n àwọn a ti sọ di aláìmọ́ ba ń sọ ni di mímọ́ fún ìwẹ̀nùmọ́ ara: 14 mélòó mélòó ni ̀jẹ̀ Kristi, ẹni, nípa ̀ayérayé, ó fi ara rẹ̀ ẹbọ Ọlọ́run láìní àbàwọ́n, yóò wẹ èérí ọkàn yín kúrò nínú òkú iṣẹ́ láti sin Ọlọ́run alààyè?

15 Àti nítorí èyí ni ó ṣe jẹ́ alárinà májẹ̀tuntun ikú ti ń bẹ fún ìdáǹdè àwọn ìrékọjá ti o lábẹ́ májẹ̀ìṣáájú, àwọn a ti ìlérí ogún àìnípẹ̀kun gbà.

16 Nítorí níbi ìwé ogún gbé , ikú ẹni o ṣe é ṣe àìsí pẹ̀; 17 nítorí ìwé ogún agbára lẹ́yìn ìgbà ènìyàn , nítorí agbára rárá nígbà ẹni o ṣè e ń bẹ láààyè. 18 Nítorí náà ni a ṣe ya májẹ̀ìṣáájú pàápàá mímọ́ láìsí ̀jẹ̀. 19 Nítorí nígbà Mose ti sọ gbogbo àṣẹ nípa ti òfin fún gbogbo àwọn ènìyàn, ó ̀jẹ̀ ọmọ màlúù àti ti ewúrẹ́, pẹ̀omi, àti òwú òdòdó, àti ewé hísópù ó fi wọ́n àti ìwé pàápàá àti gbogbo ènìyàn. 20 , "Èyí ̀jẹ̀ májẹ̀Ọlọ́run pàṣẹ fún yín." 21 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni ó fi ̀jẹ̀ wọ́n àgọ́, àti gbogbo ohun èlò ìsìn. 22 Ó fẹ́rẹ̀ jẹ́ ohun gbogbo ni a fi ̀jẹ̀ wẹ̀gẹ́gẹ́ òfin; àti láìsí ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ìdáríjì.

23 Nítorí náà a ṣàì fi ìwọ̀nyí àwọn àpẹẹrẹ ohun ń bẹ lọ́run mọ́; ṣùgbọ́n ó yẹ a fi ẹbọ ó sàn ju ìwọ̀nyí lọ wẹ àwọn ohun ̀run pàápàá mọ́; ṣùgbọ́n ó yẹ a fi ẹbọ ó sàn ju ìwọ̀nyí lọ wẹ àwọn ohun ̀run pàápàá mọ́. 24 Nítorí Kristi wọ ibi mímọ́ a fi ọwọ́ ṣe lọ i ṣe àpẹẹrẹ ti òtítọ́; ṣùgbọ́n ó lọ ̀run pàápàá, nísinsin yìí láti farahàn iwájú Ọlọ́run fún wa. 25 í i ṣe ó máa fi ara rẹ̀ ẹbọ nígbàkígbà, olórí àlùfáà máa ń wọ inú Ibi Mímọ́ Jùlọ lọ lọ́dọọdún ti òun pẹ̀̀jẹ̀ ti í ṣe tirẹ̀, 26 bẹ́̀ ni, òun ìbá máa jìyà nígbàkígbà láti ìpìlẹ̀ ayé. Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ni ó fi ara hàn lẹ́̀kan ṣoṣo lópin ayé láti mu ̀ṣẹ̀ kúrò nípa ẹbọ ara rẹ̀. 27 Níwọ́n a ti fi lélẹ̀ fún gbogbo ènìyàn láti lẹ́̀kan ṣoṣo, ṣùgbọ́n lẹ́yìn èyí ìdájọ́, 28 bẹ́̀ ni Kristi pẹ̀lẹ́yìn a ti fi ẹbọ lẹ́̀kan ṣoṣo láti ru ̀ṣẹ̀ ̀pọ̀lọpọ̀, yóò farahàn ìgbà kejì láìsí ̀ṣẹ̀ fún àwọn n wo ̀rẹ̀ fún ìgbàlà.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-