Publicidade

Joel 2

Àwọn jagunjagun eṣú

1 fun ìpè Sioni,

fún ìpè ìdágìrì òkè mímọ́ mi.

Jẹ́ àwọn ará ilẹ̀ náà wárìrì,

nítorí ọjọ́ Olúwa ń bọ̀ ,

nítorí ó dẹ̀dẹ̀.

2 Ọjọ́ òkùnkùn àti ìrọ́kẹ̀kẹ̀,

ọjọ́ ìkùùkuu àti òkùnkùn biribiri.

ọyẹ́ òwúrọ̀ ti í la bo orí àwọn òkè ńlá:

àwọn ènìyàn ńlá àti alágbára; ya ,

ti ti ì irú rẹ̀ ,

bẹ́̀ ni irú rẹ̀ yóò mọ́ lẹ́yìn rẹ̀, títí ọdún ìran ìran.

3 Iná ń níwájú wọ́n;

ọwọ́ iná ń lẹ́yìn wọn.

Ilẹ̀ náà dàbí ọgbà Edeni níwájú wọn,

àti lẹ́yìn wọn ahoro ijù;

nítòótọ́, ohun yóò bọ́ lọ́wọ́ wọn.

4 Ìrí wọn dàbí ìrí àwọn ẹṣin;

wọ́n ń sáré lọ àwọn ẹlẹ́ṣin ogun.

5 ariwo kẹ̀kẹ́ ogun ni

wọn ń fo orí òkè

ariwo ̀wọ́-iná ń koríko gbígbẹ,

akọni ènìyàn a kójọ fún ogun.

6 ojú wọn, àwọn ènìyàn yóò jẹ ìrora púpọ̀:

gbogbo ojú yóò ṣú dudu.

7 Wọn yóò sáré bi àwọn alágbára;

wọn yóò gùn odi ọkùnrin ológun;

olúkúlùkù wọn yóò rìn lọ ̀rẹ̀,

wọn yóò kúrò ni ̀wọn.

8 Bẹ́̀ ni ẹnìkan yóò kọlu ẹnìkejì rẹ̀;

olúkúlùkù wọn yóò rìn ̀rẹ̀,

nígbà wọn ṣubú idà

wọn yóò gbọgbẹ́.

9 Wọn yóò sáré síwá sẹ́yìn ìlú;

wọn yóò súré lórí odi,

wọn yóò gùn orí ilé;

wọn yóò gbà ojú fèrèsé wọ̀ inú ilé olè.

10 Ayé yóò níwájú wọn;

àwọn ̀run yóò wárìrì;

oòrùn àti òṣùpá yóò ṣókùnkùn,

àwọn ìràwọ̀ yóò ìmọ́lẹ̀ wọn sẹ́yìn.

11 Olúwa yóò ramúramù

jáde níwájú ogun rẹ̀:

nítorí ibùdó rẹ̀ tóbi gidigidi;

nítorí alágbára òun, n ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ;

nítorí ọjọ́ Olúwa tóbi ó ̀gidigidi;

ara ta ni ó gbà á?

Fa ọkàn rẹ ya

12 "Ǹjẹ́ nítorí náà nísinsin yìí," ni Olúwa ,

"fi gbogbo ọkàn yín yípadà mi,

àti pẹ̀àwẹ̀, àti pẹ̀ẹkún, àti pẹ̀̀fọ̀."

13 fa ọkàn yín ya,

í í ṣe aṣọ yín,

yípadà Olúwa Ọlọ́run yín,

nítorí o pọ̀ oore-ọ̀fẹ́,

ó kún fun àánú, ó lọ́ra láti bínú,

ó ṣeun púpọ̀, ó ronúpìwàdà láti ṣe búburú.

14 Ta ni ó mọ̀ òun yóò yípadà, o ronúpìwàdà,

ó fi ìbùkún sílẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀—

àní ọrẹ-jíjẹ àti ọrẹ mímu

fún Olúwa Ọlọ́run yín?

15 fún ìpè Sioni,

ya àwẹ̀ kan mímọ́,

pe àjọ ó ni ìrònú.

16 àwọn ènìyàn jọ,

ya ìjọ mímọ́;

pe àwọn àgbàgbà jọ,

àwọn ọmọdé jọ,

àti àwọn ń ọmú,

jẹ ọkọ ìyàwó kúrò nínú ìyẹ̀rẹ̀.

ìyàwó kúrò nínú iyàrá rẹ̀.

17 Jẹ́ àwọn àlùfáà, àwọn ìránṣẹ́ Olúwa,

sọkún láàrín ìloro àti pẹpẹ.

jẹ́ wọn , "àwọn ènìyàn rẹ , Olúwa.

ṣe fi ìní rẹ fun ̀gàn,

yóò di òwe àárín àwọn kèfèrí.

Èéṣe wọn yóò fi láàrín àwọn ènìyàn ,

Ọlọ́run wọn ha da?’ "

Olúwa ra Juda padà

18 Nígbà náà Olúwa yóò jowú fún ilẹ̀ rẹ̀,

yóò káàánú fún ènìyàn rẹ̀.

19 Nítòótọ́, Olúwa yóò wọn lóhùn, yóò fun àwọn ènìyàn rẹ̀ :

"ó èmi yóò rán ọkà, àti ọtí wáìnì tuntun, àti òróró i yín,

a ó fi wọn tẹ́ yín lọ́rùn;

Èmi yóò fi yín ṣe ̀gàn mọ́

láàrín àwọn aláìkọlà.

20 "Ṣùgbọ́n èmi yóò ogun àríwá jìnnà réré kúrò lọ́dọ̀ yín,

èmi yóò e lọ ilẹ̀ ó ṣá, ó di ahoro,

pẹ̀ojú rẹ̀ Òkun ìlà-oòrùn,

àti ̀yìn rẹ̀ ìwọ̀-oòrùn Òkun.

Òórùn rẹ̀ yóò gòkè,

òórùn búburú rẹ̀ yóò gòkè."

Nítòótọ́ ó ti ṣe ohun ńlá.

21 bẹ̀, ìwọ ilẹ̀;

jẹ́ inú rẹ̀ dùn o yọ̀,

nítorí Olúwa ti ṣe ohun ńlá.

22 bẹ̀, ẹranko igbó,

nítorí pápá oko aginjù ń .

Nítorí igi ń so èso rẹ̀,

igi ̀pọ̀tọ́ àti àjàrà ń so èso ̀rọ̀ wọn.

23 jẹ́ inú yín dùn, ̀yin ọmọ Sioni,

yọ̀ nínú Olúwa Ọlọ́run yín,

nítorí ó ti fi àkọ́rọ̀ òjò fún yín ó ti tọ́,

Òun ti òjò rọ̀ sílẹ̀ fún un yín,

àkọ́rọ̀ àti àrọ̀kúrò òjò oṣù kìn-ín-ní.

24 Àwọn ilẹ̀ ìpakà yóò kún fún ọkà;

àti ọpọ́n wọn yóò sàn jáde

pẹ̀ọtí wáìnì tuntun àti òróró.

25 "Èmi yóò ọdún wọ̀nyí ti eṣú jẹ run padà fún un yín.

Èyí eṣú agénijẹ àti eṣú jewéjewé

ọwọ́ eṣú agénijẹ àti kòkòrò ajẹnirun mìíràn ti fi jẹ

àwọn ogun ńlá mi mo rán àárín yín.

26 ̀yin yóò ni ̀pọ̀lọpọ̀ láti jẹ, títí ̀yin yóò fi

ó yín orúkọ Olúwa Ọlọ́run yín,

ẹni ó fi ìyanu yín ;

ojú yóò ti àwọn ènìyàn mi láéláé.

27 ̀yin yóò mọ̀ , èmi láàrín Israẹli,

àti ; Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín,

àti ẹlòmíràn,

ojú yóò ti àwọn ènìyàn láéláé.

Ọjọ́ Olúwa

28 "Yóò ṣe níkẹyìn ọjọ́,

èmi yóò nínú ̀ara ènìyàn gbogbo;

àwọn ọmọ yín ọkùnrin àti àwọn ọmọ yín obìnrin yóò máa sọtẹ́lẹ̀,

àwọn arúgbó yín yóò máa àlá,

àwọn ̀dọ́mọkùnrin yín yóò máa ríran.

29 Àti pẹ̀ara àwọn ọmọ ̀dọ̀ ọkùnrin,

àti ara àwọn ọmọ ̀dọ̀ obìnrin,

èmi yóò ̀jáde ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì.

30 Èmi yóò fi iṣẹ́ ìyanu hàn ọrun

àti ayé,

̀jẹ̀ àti iná, àti ̀wọ́n èéfín.

31 A á sọ oòrùn di òkùnkùn,

àti òṣùpá di ̀jẹ̀,

ọjọ́ ńlá àti ọjọ́ ̀Olúwa .

32 Yóò ṣe, ẹnikẹ́ni ó ba

orúkọ Olúwa a ó gbàlà,

nítorí òkè Sioni àti Jerusalẹmu

ìgbàlà yóò gbé ,

Olúwa ti ,

àti nínú àwọn

ìyókù Olúwa yóò .

Veja também

Publicidade
Joel
Ver todos os capítulos de Joel
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-