Publicidade

Jonas 2

Àdúrà Jona

1 Nígbà náà ni Jona gbàdúrà Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ láti inú ẹja náà , 2 Ó :

"Nínú ìpọ́njú mi ni mo kígbe Olúwa,

òun gbọ́ ohùn mi.

Mo kígbe láti inú ipò òkú, mo fún ìrànwọ́,

ìwọ gbọ́ ohùn mi.

3 Nítorí ìwọ ti sọ sínú ibú,

àárín Òkun,

ìṣàn omi mi káàkiri;

gbogbo bíbì omi àti rírú omi

rékọjá lórí mi.

4 Nígbà náà ni mo ,

A ta kúrò níwájú rẹ;

ṣùgbọ́n síbẹ̀ èmi yóò tún

máa wo ìhà tẹmpili mímọ́ rẹ.

5 Omi mi káàkiri, àní títí ọkàn;

ibú mi káàkiri,

a fi koríko odò mi lórí.

6 Èmi sọ̀kalẹ̀ lọ ìsàlẹ̀ àwọn òkè ńlá;

ilẹ̀ ayé pẹ̀ìdènà rẹ̀ mi títí:

ṣùgbọ́n ìwọ ti ̀mi sókè láti inú ibú ,

Olúwa Ọlọ́run mi.

7 "Nígbà ó rẹ ọkàn mi nínú mi,

èmi rántí rẹ, Olúwa,

àdúrà mi ̀dọ̀ rẹ,

nínú tẹmpili mímọ́ rẹ.

8 "Àwọn ń fàmọ́ òrìṣà èké

kọ àánú ara wọn sílẹ̀.

9 Ṣùgbọ́n èmi yóò fi orin ọpẹ́, ẹbọ .

Èmi yóò san ̀jẹ́ mo ti jẹ́.

Ìgbàlà láti ̀dọ̀ Olúwa.’ "

10 Olúwa pàṣẹ fún ẹja náà, ó pọ Jona orí ilẹ̀ gbígbẹ.

Veja também

Publicidade
Jonas
Ver todos os capítulos de Jonas
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-