Publicidade

João 11

Ikú Lasaru

1 Ara ọkùnrin kan , Lasaru, ará Betani, í ṣe ìlú Maria àti Marta arábìnrin rẹ̀. 2 Maria náà ni ẹni ó fi òróró ìkunra kun Olúwa, ó fi irun orí rẹ̀ ún, arákùnrin rẹ̀ ni Lasaru í ṣe, ara ẹni . 3 Nítorí náà, àwọn arábìnrin rẹ̀ ránṣẹ́ i, , "Olúwa, ó, ara ẹni ìwọ fẹ́ràn ."

4 Nígbà Jesu gbọ́, ó , "Àìsàn yìí í ṣe ikú, ṣùgbọ́n fún ògo Ọlọ́run, a yin Ọmọ Ọlọ́run lógo nípasẹ̀ rẹ̀." 5 Jesu fẹ́ràn Marta, àti arábìnrin rẹ̀ àti Lasaru. 6 Nítorí náà, nígbà ó ti gbọ́ , ara rẹ̀ , ó gbé ọjọ́ méjì i níbìkan náà ó gbé . 7 Ǹjẹ́ lẹ́yìn èyí ni ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "jẹ́ a tún padà lọ Judea."

8 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ fún un , "Rabbi, àìpẹ́ yìí ni àwọn Júù ń ̀láti sọ ́ òkúta; ìwọ tún padà lọ síbẹ̀?"

9 Jesu dáhùn , "Wákàtí méjìlá kọ́ ni ó bẹ nínú ̀sán kan ? ẹnìkan rìn ̀sán, yóò kọsẹ̀, nítorí ó ìmọ́lẹ̀ ayé yìí. 10 Ṣùgbọ́n ẹnìkan rìn òru, yóò kọsẹ̀, nítorí ìmọ́lẹ̀ nínú rẹ̀."

11 Nǹkan wọ̀nyí ni ó sọ, lẹ́yìn èyí ó fún wọn , "Lasaru ̀rẹ́ wa sùn; ṣùgbọ́n èmi ń lọ èmi ó i dìde nínú orun rẹ̀."

12 Nítorí náà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ fún un , "Olúwa, ó ṣe ó sùn, yóò sàn." 13 Ṣùgbọ́n Jesu ń sọ ti ikú rẹ̀, ṣùgbọ́n wọ́n , ó ń sọ ti orun sísùn.

14 Nígbà náà ni Jesu fún wọn gbangba , "Lasaru ti . 15 Èmi yọ̀ nítorí yín, èmi níbẹ̀. le gbàgbọ́; ṣùgbọ́n jẹ́ a lọ sọ́dọ̀ rẹ̀."

16 Nítorí náà Tomasi, ẹni à ń Didimu, fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ẹgbẹ́ rẹ̀ , "jẹ́ àwa náà lọ, a a pẹ̀."

Jesu tu àwọn arábìnrin rẹ̀ nínú

17 Nítorí náà nígbà Jesu , ó i a ti tẹ́ sínú ibojì ọjọ́ mẹ́rin , 18 ǹjẹ́ Betani súnmọ́ Jerusalẹmu ibùsọ̀ mẹ́̀́dógún. 19 ̀pọ̀ nínú àwọn Júù sọ́dọ̀ Marta àti Maria láti wọ́n nínú nítorí ti arákùnrin wọn. 20 Nítorí náà, nígbà Marta gbọ́ Jesu ń bọ̀ , ó jáde lọ pàdé rẹ̀, ṣùgbọ́n Maria jókòó nínú ilé.

21 Nígbà náà, ni Marta fún Jesu , "Olúwa, ìbá ṣe ìwọ ti níhìn-ín, arákùnrin mi . 22 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí náà, mo mọ̀ , ohunkóhun ìwọ béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run, Ọlọ́run yóò fi fún ."

23 Jesu fún un , "Arákùnrin rẹ yóò jíǹde."

24 Marta fún un , "Mo mọ̀ yóò jíǹde àjíǹde ìkẹyìn."

25 Jesu fún un , "Èmi ni àjíǹde àti ìyè, ẹni ó gbà gbọ́, ó tilẹ̀ , yóò . 26 Ẹnikẹ́ni ó ń bẹ láààyè, ó gbà gbọ́, yóò láéláé ìwọ gbà èyí gbọ́?"

27 Ó fún un , "Bẹ́̀ ni, Olúwa, èmi gbàgbọ́ , ìwọ ni Kristi náà Ọmọ Ọlọ́run, ẹni ń bọ̀ ayé."

28 Nígbà ó ti èyí tan, ó lọ, ó pe Maria arábìnrin rẹ̀ sẹ́yìn , "Olùkọ́ , ó ń ́." 29 Nígbà ó gbọ́, ó dìde lọ́gán, ó sọ́dọ̀ rẹ̀. 30 Jesu ì wọ ìlú, ṣùgbọ́n ó ibi kan náà Marta ti pàdé rẹ̀. 31 Nígbà àwọn Júù ó lọ́dọ̀ rẹ̀ nínú ilé, wọ́n ń ú nínú Maria ó dìde kánkán, ó jáde, wọ́n tẹ̀, wọ́n ṣe ó ń lọ ibojì láti sọkún níbẹ̀.

32 Nígbà Maria ibi Jesu , ó i, ó wólẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ̀, ó fún un , "Olúwa, ìbá ṣe ìwọ ti níhìn-ín, arákùnrin mi ."

33 Nígbà Jesu i, ó ń sọkún, àti àwọn Júù ó a ń sọkún pẹ̀rẹ̀, ó kérora nínú ̀, inú rẹ̀ bàjẹ́. 34 Ó , "Níbo ni ̀yin gbé tẹ́ ?"

Wọ́n fún un , "Olúwa, ó."

35 Jesu sọkún.

36 Nítorí náà àwọn Júù , "ó ó ti fẹ́ràn rẹ̀ !"

37 Àwọn kan nínú wọn , "Ọkùnrin yìí, ẹni ó la ojú afọ́, ṣe é ọkùnrin yìí ?"

Jesu òkú Lasaru dìde

38 Nígbà náà ni Jesu tún kérora nínú ara rẹ̀, ó ibojì, ó jẹ́ ihò, a gbé òkúta ẹnu rẹ̀. 39 Jesu , "gbé òkúta náà kúrò!"

Marta, arábìnrin ẹni ó náà fún un , "Olúwa, ó ti ń rùn nísinsin yìí, nítorí ó di ọjọ́ kẹrin ó ."

40 Jesu fún un , "Èmi ti fún , ìwọ gbàgbọ́, ìwọ yóò ògo Ọlọ́run?"

41 Nígbà náà ni wọ́n gbé òkúta náà kúrò (níbi a tẹ́ ). Jesu gbé ojú rẹ̀ sókè, ó , "Baba, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ nítorí ìwọ gbọ́ tèmi. 42 Èmi ti mọ̀ , ìwọ a máa gbọ́ ti èmi nígbà gbogbo, ṣùgbọ́n nítorí ìjọ ènìyàn ó dúró yìí ni mo ṣe i, wọn ba à gbàgbọ́ ìwọ ni ó rán mi."

43 Nígbà ó bẹ́̀ tan, ó kígbe lóhùn rara , "Lasaru, jáde ." 44 Ẹni ó náà jáde , a fi aṣọ òkú tọwọ́ tẹsẹ̀ a fi gèlè í lójú.

Jesu fún wọn , "u, jẹ́ ó máa lọ!"

Àwọn alábojútó pinnu láti pa Jesu

45 Nítorí náà ni ̀pọ̀ àwọn Júù ó sọ́dọ̀ Maria, wọ́n ohun Jesu ṣe, ṣe gbà á gbọ́. 46 Ṣùgbọ́n àwọn ẹlòmíràn nínú wọn tọ àwọn Farisi lọ, wọ́n sọ fún wọn ohun Jesu ṣe. 47 Nígbà náà ni àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi pe ìgbìmọ̀ jọ.

Wọ́n , "Kín ni yóò jẹ àṣeyọrí wa? Nítorí ọkùnrin yìí ń ṣe ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àmì. 48 àwa fi í sílẹ̀ bẹ́̀, gbogbo ènìyàn ni yóò gbà á gbọ́, àwọn ará Romu yóò gba ilẹ̀ àti orílẹ̀-èdè wa pẹ̀."

49 Ṣùgbọ́n Kaiafa, ̀kan nínú wọn, ẹni í ṣe olórí àlùfáà ọdún náà, ó fún wọn , "̀yin mọ ohunkóhun rárá! 50 Bẹ́̀ ni ronú , ó ṣàǹfààní fún wa, ènìyàn kan fún àwọn ènìyàn gbogbo orílẹ̀-èdè ba à ṣègbé."

51 í ṣe fún ara rẹ̀ ni ó sọ èyí ṣùgbọ́n ó ti jẹ́ olórí àlùfáà ọdún náà, ó sọtẹ́lẹ̀ , Jesu yóò fún orílẹ̀-èdè náà, 52 í ṣe kìkì fún orílẹ̀-èdè náà nìkan, ṣùgbọ́n fún àwọn ọmọ Ọlọ́run ó fọ́nká kiri, ó le wọn papọ̀, ó sọ wọ́n di ̀kan. 53 Nítorí náà, láti ọjọ́ náà lọ ni wọ́n ti jọ gbìmọ̀ pọ̀ láti pa á.

54 Nítorí náà Jesu rìn gbangba láàrín àwọn Júù mọ́; ṣùgbọ́n ó ti ibẹ̀ lọ ìgbèríko kan ó súnmọ́ aginjù, ìlú ńlá kan a ń Efraimu, níbẹ̀ ni ó pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.

55 Àjọ ìrékọjá àwọn Júù súnmọ́ etílé, ̀pọ̀lọpọ̀ láti ìgbèríko gòkè lọ Jerusalẹmu ṣáájú ìrékọjá, láti ya ara wọn mímọ́. 56 Nígbà náà ni wọ́n ń Jesu, wọ́n ń ara wọn sọ̀, wọ́n ti dúró tẹmpili, , "Kín ni ẹyin ti ó yóò àjọ?" 57 Ǹjẹ́ àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi ti pàṣẹ ẹnìkan mọ ibi ó gbé , ó fi í hàn, wọn ba à un.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-