Publicidade

João 13

Jesu wẹ ẹsẹ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀

1 Ǹjẹ́ àjọ ìrékọjá , nígbà Jesu mọ̀ , wákàtí rẹ̀ tan, òun ó ti ayé yìí kúrò lọ sọ́dọ̀ Baba, fífẹ́ ó fẹ́ àwọn tirẹ̀ ó ayé, ó fẹ́ wọn títí òpin.

2 wọ́n ti ń jẹ oúnjẹ alẹ́, èṣù ti fi í ọkàn Judasi Iskariotu ọmọ Simoni láti fi í hàn; 3 Jesu ti mọ̀ Baba ti fi ohun gbogbo òun lọ́wọ́, àti lọ́dọ̀ Ọlọ́run ni òun ti , òun ń lọ sọ́dọ̀ Ọlọ́run; 4 Ó dìde ìdí oúnjẹ alẹ́, ó fi agbádá rẹ̀ lélẹ̀ apá kan; nígbà ó aṣọ ìnura, ó di ara rẹ̀ àmùrè. 5 Lẹ́yìn náà, ó bu omi sínú àwokòtò kan, ó bẹ̀rẹ̀ í máa wẹ ẹsẹ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó ń fi aṣọ ìnura ó fi di àmùrè wọ́n.

6 Nígbà náà ni ó ̀dọ̀ Simoni Peteru, òun fún un , "Olúwa, ìwọ yóò ha wẹ ẹsẹ̀ mi?"

7 Jesu a lóhùn, ó fún un , "Ohun èmi ń ṣe ni ìwọ mọ̀ nísinsin yìí; ṣùgbọ́n yóò ìkẹyìn."

8 Peteru fún un , "Ìwọ yóò wẹ̀ ẹsẹ̀ mi láé."

Jesu dalóhùn , "èmi wẹ̀ ́, ìwọ ìpín ̀dọ̀ mi."

9 Simoni Peteru fún ún , "Olúwa, í ṣe ẹsẹ̀ mi nìkan, ṣùgbọ́n àti ọwọ́ àti orí mi pẹ̀."

10 Jesu fún un , "Ẹni a wẹ̀ tún fẹ́ ju a ṣan ẹsẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ó mọ́ níbi gbogbo: ̀yin mọ́, ṣùgbọ́n í ṣe gbogbo yín." 11 Nítorí ó mọ ẹni yóò fi òun hàn; nítorí náà ni ó ṣe , í ṣe gbogbo yín ni ó mọ́.

12 Nítorí náà lẹ́yìn ó wẹ ẹsẹ̀ wọn tán, ó ti agbádá rẹ̀, ó tún jókòó, ó fún wọn , "̀yin mọ ohun mo ṣe yín ? 13 ̀yin ń Olùkọ́’ àti Olúwa,̀yin rere; bẹ́̀ ni mo jẹ́. 14 Ǹjẹ́ èmi í ṣe Olúwa àti olùkọ́ yín wẹ ẹsẹ̀ yín, ó tọ́ ̀yin pẹ̀máa wẹ ẹsẹ̀ ara yín. 15 Nítorí mo fi àpẹẹrẹ fún yín, ̀yin máa ṣe gẹ́gẹ́ mo ti ṣe yín. 16 Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo fún yín, ọmọ ̀dọ̀ tóbi ju ̀rẹ̀ lọ, bẹ́̀ ni ẹni a rán tóbi ju ẹni ó rán an lọ. 17 ̀yin mọ nǹkan wọ̀nyí, alábùkún fún ni yín, ̀yin ń ṣe wọ́n!

Jesu sọtẹ́lẹ̀ ẹnìkan yóò fi òun hàn

18 "í ṣe ti gbogbo yín ni mo ń sọ, èmi mọ àwọn mo yàn, ṣùgbọ́n Ìwé Mímọ́ à ṣẹ, Ẹni ń mi jẹun pọ̀ gbé gìgísẹ̀ rẹ̀ mi.

19 "Láti ìsinsin yìí lọ ni mo fún un yín ó , nígbà ó , ̀yin gbàgbọ́ èmi ni. 20 Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo fún un yín, ẹni ó gba ẹnikẹ́ni mo rán, ó gbà ; ẹni ó gbà , ó gba ẹni ó rán mi."

21 Nígbà Jesu ti nǹkan wọ̀nyí tán, ọkàn rẹ̀ dàrú nínú rẹ̀, ó jẹ́rìí, ó , "Lóòótọ́ lóòótọ́ ni mo fún un yín , ̀kan nínú yín yóò ."

22 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń ara wọn lójú, wọ́n ń ṣiyèméjì ti ẹni ó . 23 Ǹjẹ́ ẹnìkan rọ̀gbọ̀àyà Jesu, ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ẹni Jesu fẹ́ràn. 24 Nítorí náà ni Simoni Peteru ṣàpẹẹrẹ i, ó fún un , "fún wa ti ẹni o ń sọ."

25 Ẹni ó ń rọ̀gún àyà Jesu fún un , "Olúwa, ta ni í ṣe?"

26 Nítorí náà Jesu dáhùn , "Òun náà ni, ẹni mo fi àkàrà fún nígbà mo fi run àwo." Nígbà ó fi run ún tan, ó fi fún Judasi Iskariotu ọmọ Simoni. 27 kété Judasi gba àkàrà náà ni Satani wọ inú rẹ̀ lọ.

Nítorí náà Jesu fún un , "Ohun ìwọ ń ṣe , yára ṣe é kánkán." 28 ẹnìkan níbi tábìlì ó mọ ìdí ó ṣe sọ èyí fún un. 29 Nítorí àwọn mìíràn nínú wọn , nítorí Judasi ni ó ni àpò, ni Jesu fi fún un , ra nǹkan wọ̀n-ọn-nì a le ṣe aláìní fún àjọ náà; tàbí ó fi nǹkan fún àwọn tálákà. 30 Nígbà ó ti gbà òkèlè náà tan, ó jáde lójúkan náà àkókò náà si jẹ òru.

Jesu sọtẹ́lẹ̀ Peteru yóò sẹ́ òun

31 Nítorí náà nígbà ó jáde lọ tan, Jesu , "Nísinsin yìí ni a yin Ọmọ Ènìyàn lógo, a yin Ọlọ́run lógo nínú rẹ̀. 32 a yin Ọlọ́run lógo nínú rẹ̀, Ọlọ́run yóò yìn ín lógo nínú òun tìkára rẹ̀, yóò yìn ín lógo nísinsin yìí.

33 "̀yin ọmọ mi, nígbà díẹ̀ i ni èmi pẹ̀yín. ̀yin yóò mi, àti gẹ́gẹ́ mo ti fún àwọn Júù , níbi èmi gbé ń lọ, ̀yin yóò le ; bẹ́̀ ni mo fún yín nísinsin yìí.

34 "Òfin tuntun kan ni mo fi fún yín, ̀yin ó fẹ́ ọmọnìkejì yín; gẹ́gẹ́ èmi ti fẹ́ràn yín, ̀yin ó fẹ́ràn ọmọnìkejì yín. 35 Nípa èyí ni gbogbo ènìyàn yóò fi mọ̀ , ọmọ-ẹ̀yìn mi ni ̀yin ń ṣe, nígbà ̀yin ìfẹ́ ọmọ ẹnìkejì yín."

36 Simoni Peteru fún un , "Olúwa, níbo ni ìwọ ń lọ?"

Jesu a lóhùn , "Níbi èmi ń lọ, ìwọ yóò tẹ̀nísinsin yìí; ṣùgbọ́n ìwọ yóò tọ̀ lẹ́yìn ìkẹyìn."

37 Peteru fún un , "Olúwa èéṣe èmi fi le tọ̀ ́ lẹ́hìn nísinsin yìí? Èmi ó fi ̀mi lélẹ̀ nítorí rẹ."

38 Jesu dalóhùn , "Ìwọ ó ha fi ̀rẹ lélẹ̀ nítorí mi? Lóòótọ́ lóòótọ́ ni mo fún , àkùkọ yóò kọ, ìwọ ó ṣẹ́ mi nígbà mẹ́ta!

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-