Pular para o conteúdo
Publicidade

João 18

Wọ́n Jesu

1 18.1: Mt 26.30,36; Mk 14.26,32; Lk 22.39; 2Sa 15.23. Nígbà Jesu ti sọ nǹkan wọ̀nyí tán, ó jáde pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ lọ sókè odò Kidironi, níbi àgbàlá kan , nínú èyí ó wọ̀, Òun àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.

2 Judasi, ẹni ó fihàn, mọ ibẹ̀ pẹ̀, nítorí nígbà púpọ̀ ni Jesu máa ń lọ síbẹ̀ pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. 3 18.3-11: Mt 26.47-56; Mk 14.43-50; Lk 22.47-53.Nígbà náà ni Judasi, lẹ́yìn ó ti gba ẹgbẹ́ ọmọ-ogun, àti àwọn oníṣẹ́ láti ̀dọ̀ àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi síbẹ̀ ti àwọn ti fìtílà àti ògùṣọ̀, àti ohun ìjà.

4 18.4: Jh 6.64; 13.1. Nítorí náà Jesu ti mọ ohun gbogbo ń bọ̀ òun, ó jáde lọ, ó fún wọn , "Ta ni ẹyin ń ?"

5 Wọ́n a lóhùn , "Jesu ti Nasareti."

Jesu fún wọn , "Èmi nìyí." (Àti Judasi ̀dàlẹ̀, dúró pẹ̀wọn). 6 Nítorí náà ó ti fún wọn , "Èmi nìyí," wọ́n sẹ́yìn, wọ́n ṣubú lulẹ̀.

7 Nítorí náà ó tún bi wọ́n léèrè, , "Ta ni ń ?"

Wọ́n , "Jesu ti Nasareti."

8 Jesu dáhùn , "Mo ti fún yín , èmi nìyí. Ǹjẹ́ èmi ni ń , jẹ́ àwọn wọ̀nyí máa lọ." 9 18.9: Jh 17.12; 6.39.̀rọ̀ ó ṣẹ, èyí , "Àwọn ìwọ fi fún mi, èmi sọ ̀kan nínú wọn."

10 Nígbà náà ni Simoni Peteru ẹni ó idà, á yọ, ó ṣá ọmọ ̀dọ̀ olórí àlùfáà, ó etí ̀tún rẹ̀ sọnù. Orúkọ ìránṣẹ́ náà a máa jẹ́ Makọọsi.

11 18.11: Mk 10.38; 14.36. Nítorí náà Jesu fún Peteru , "Tẹ idà rẹ bọ inú àkọ̀ rẹ, ago baba ti fi fún mi, èmi ó ṣe aláìmu ún ?"

Jesu níwájú Annasi

12 18.12-13: Mt 26.57; Mk 14.53; Lk 22.54; 3.2. Nígbà náà ni ẹgbẹ́ ọmọ-ogun àti olórí ̀ṣọ́, àti àwọn oníṣẹ́ àwọn Júù Jesu, wọ́n é. 13 Wọ́n kọ́kọ́ á lọ sọ́dọ̀ Annasi; nítorí òun ni àna Kaiafa, ẹni í ṣe olórí àlùfáà ọdún náà. 14 18.14: Jh 11.49-51.Kaiafa à ni ẹni ó ti àwọn Júù gbìmọ̀ , ó ṣàǹfààní ènìyàn kan fún àwọn ènìyàn.

Peteru sẹ́ Jesu àkọ́kọ́

15 18.15-16: Mt 26.58; Mk 14.54; Lk 22.54. Simoni Peteru ń tọ Jesu lẹ́yìn, àti ọmọ-ẹ̀yìn mìíràn kan: ọmọ-ẹ̀yìn náà jẹ́ ẹni mọ̀ fún olórí àlùfáà, ó Jesu wọ ààfin olórí àlùfáà lọ. 16 Ṣùgbọ́n Peteru dúró ẹnu-ọ̀lóde. Nígbà náà ni ọmọ-ẹ̀yìn mìíràn náà í ṣe ẹni mọ̀ fún olórí àlùfáà jáde, ó olùṣọ́náà sọ̀rọ̀, ó Peteru wọlé.

17 18.17-18: Mt 26.69-72; Mk 14.66-69; Lk 22.56-58. Nígbà náà ni ọmọbìnrin náà ń ṣọ́ ẹnu-ọ̀fún Peteru , "Ìwọ pẹ̀ha ń ṣe ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ọkùnrin yìí ?"

Ó , "Èmi kọ́."

18 Àwọn ọmọ ̀dọ̀ àti àwọn aláṣẹ dúró níbẹ̀, àwọn ẹni ó ti dáná nítorí ti òtútù , wọ́n ń yáná, Peteru dúró pẹ̀wọn, ó ń yáná.

Alábojútó àlùfáà fi ̀rọ̀ Jesu lẹ́nu

19 18.19-23: Mt 26.59-66; Mk 14.55-64; Lk 22.67-71. Nígbà náà ni olórí àlùfáà bi Jesu léèrè ti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, àti ti ̀kọ́ rẹ̀.

20 Jesu a lóhùn , "Èmi ti sọ̀rọ̀ gbangba fún aráyé; nígbà gbogbo ni èmi ń kọ́ni nínú Sinagọgu, àti tẹmpili níbi gbogbo àwọn Júù ń péjọ , èmi sọ ohun kan ìkọ̀kọ̀. 21 Èéṣe ìwọ fi ń bi léèrè? Béèrè lọ́wọ́ àwọn ó ti gbọ́ ̀rọ̀ mi, ohun mo fún wọn: ó, àwọn wọ̀nyí mọ ohun èmi ."

22 ó ti èyí tan, ̀kan nínú àwọn aláṣẹ ó dúró í fi ọwọ́ rẹ̀ lu Jesu, , "Alábojútó àlùfáà ni ìwọ ń lóhùn bẹ́̀?"

23 18.23: Mt 5.39; Ap 23.2-5. Jesu a lóhùn , "mo sọ̀rọ̀ búburú, jẹ́rìí búburú náà, ṣùgbọ́n rere ni, èéṣe ìwọ fi ń ?" 24 18.24: Jh 18.13; Lk 3.2.Nítorí Annasi rán an lọ dídè sọ́dọ̀ Kaiafa olórí àlùfáà.

Peteru sẹ́ Jesu ìgbà kejì àti ìgbà kẹta

25 18.25-27: Mt 26.73-75; Mk 14.70-72; Lk 22.59-62. Ṣùgbọ́n Simoni Peteru dúró, ó ń yáná. Nígbà náà ni wọ́n fún un , "Ìwọ pẹ̀ha jẹ́ ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀?"

Ó sẹ́, , "Èmi kọ́."

26 ̀kan nínú àwọn ọmọ ̀dọ̀ olórí àlùfáà, ó jẹ́ ìbátan ẹni Peteru etí rẹ̀ sọnù, , "Èmi ko ha pẹ̀rẹ̀ àgbàlá?" 27 Peteru tún sẹ́: lójúkan náà àkùkọ kọ.

Jesu níwájú Pilatu

28 18.28: Jh 11.55; Mt 27.1-2; Mk 15.1; Lk 23.1. Nígbà náà, wọ́n fa Jesu láti ̀dọ̀ Kaiafa lọ ibi gbọ̀ngàn ìdájọ́, ó jẹ́ kùtùkùtù òwúrọ̀; àwọn tìkára wọn wọ inú gbọ̀ngàn ìdájọ́, wọn ṣe di aláìmọ́, ṣùgbọ́n wọn jẹ àsè ìrékọjá. 29 18.29-38: Mt 27.11-14; Mk 15.2-5; Lk 23.2-3.Nítorí náà Pilatu jáde tọ̀ wọ́n lọ, ó , "̀sùn kín ̀yin fun ọkùnrin yìí?"

30 Wọ́n dáhùn fún un , "Ìbá ṣe ọkùnrin yìí ń hùwà ibi, a á lọ́wọ́."

31 Nítorí náà Pilatu fún wọn , "un tìkára yín, ṣe ìdájọ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ òfin yín."

Nítorí náà ni àwọn Júù fún un , "tọ́ fún wa láti pa ẹnikẹ́ni." 32 18.32: Jh 3.14; 12.32.̀rọ̀ Jesu ba à ṣẹ, èyí ó sọ ó ń ṣàpẹẹrẹ irú ikú òun yóò .

33 Nítorí náà, Pilatu tún wọ inú gbọ̀ngàn ìdájọ́ lọ, ó pe Jesu, ó fún un , "Ìwọ ha ni a ni ọba àwọn Júù ?"

34 Jesu dáhùn , "Èrò ti ara rẹ ni èyí, tàbí àwọn ẹlòmíràn sọ ́ fún nítorí mi?"

35 Pilatu dáhùn , "Èmi ha jẹ́ Júù ? Àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè rẹ, àti àwọn olórí àlùfáà ni ó ́ èmi lọ́wọ́, kín ìwọ ṣe?"

36 18.36: Jh 6.15; Mt 26.53. Jesu dáhùn , "Ìjọba mi í ṣe ti ayé yìí. Ìbá ṣe ìjọba mi jẹ́ ti ayé yìí, àwọn ìránṣẹ́ mi ìbá , a ba à fi àwọn Júù lọ́wọ́, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìjọba mi í ṣe láti ìhín lọ."

37 18.37: Jh 3.32; 8.14,47; 1Jh 4.6. Nítorí náà, Pilatu fún un , "Ọba ni ́ nígbà náà?"

Jesu dáhùn , "Ìwọ , ọba ni èmi jẹ́. Nítorí èyí ni a ṣe , àti nítorí ìdí èyí ni mo ṣe ayé n jẹ́rìí òtítọ́, olúkúlùkù ẹni í ṣe ti òtítọ́ ń gbọ́ ohùn mi."

38 18.38-40: Mt 27.15-26; Mk 15.6-15; Lk 23.18-19; Ap 3.14. Pilatu fún un , "Kín ni òtítọ́?" Nígbà ó ti èyí tan, ó tún jáde tọ àwọn Júù lọ, ó fún wọn , "Èmi ̀ṣẹ̀ kan lọ́wọ́ rẹ̀. 39 Ṣùgbọ́n ̀yin àṣà kan , èmi ̀kan sílẹ̀ fún yín nígbà àjọ ìrékọjá, nítorí náà ó ha fẹ́ èmi ọba àwọn Júù sílẹ̀ fún yín ?"

40 Nítorí náà gbogbo wọn tún kígbe , "í ṣe ọkùnrin yìí, ṣe Baraba!" Ọlọ́ṣà ni Baraba.

Veja também