26 19.26: Jh 13.23; 20.2; 21.20.nígbà tí Jesu rí ìyá rẹ̀ àti ọmọ-ẹ̀yìn náà dúró, ẹni tí Jesu fẹ́ràn, ó wí fún ìyá rẹ̀ pé, "Obìnrin, wo ọmọ rẹ!" 27 Lẹ́yìn náà ni ó sì wí fún ọmọ-ẹ̀yìn náà pé, "Wo ìyá rẹ!" Láti wákàtí náà lọ ni ọmọ-ẹ̀yìn náà sì ti mú un lọ sí ilé ara rẹ̀.