Publicidade

João 6

Jesu bọ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ènìyàn

1 6.1-13: Mt 14.13-21; Mk 6.32-44; Lk 9.10-17. Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, Jesu kọjá apá kejì Òkun Galili, í ṣe Òkun Tiberia. 2 ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn tọ̀ ́ lẹ́yìn, nítorí wọ́n iṣẹ́ àmì rẹ̀ ó ń ṣe lára àwọn aláìsàn. 3 Jesu gun orí òkè lọ, níbẹ̀ ni ó gbé jókòó pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. 4 Àjọ ìrékọjá ọdún àwọn Júù súnmọ́ etílé.

5 6.5: Jh 1.43; 12.21. Ǹjẹ́ Jesu ti gbé ojú rẹ̀ sókè, ó ̀pọ̀ ènìyàn sọ́dọ̀ rẹ̀, ó fún Filipi , "Níbo ni a ó ti ra àkàrà, àwọn wọ̀nyí jẹ?" 6 Ó sọ èyí láti dán an ; nítorí òun fúnra rẹ̀ mọ ohun òun ó ṣe.

7 Filipi a lóhùn , "Àkàrà igba owó idẹ fún wọn, olúkúlùkù wọn tilẹ̀ í ju díẹ̀ jẹ."

8 6.8: Jh 1.40; 12.22. ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, Anderu, arákùnrin Simoni Peteru fún un , 9 6.9: Jh 21.9-13."Ọmọdékùnrin kan ń bẹ níhìn-ín yìí, ó ìṣù àkàrà barle márùn-ún àti ẹja wẹ́wẹ́ méjì, ṣùgbọ́n kín ni ìwọ̀nyí jẹ́ láàrín ̀pọ̀ ènìyàn wọ̀nyí?"

10 Jesu , "àwọn ènìyàn náà jókòó!" Koríko púpọ̀ níbẹ̀. Bẹ́̀ ni àwọn ọkùnrin náà jókòó; ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ènìyàn iye. 11 Jesu ìṣù àkàrà náà. Nígbà ó ti dúpẹ́, ó pín wọn fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pín wọn fún àwọn ó jókòó; bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni ẹja ìwọ̀n wọ́n ti ń fẹ́.

12 Nígbà wọ́n , ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "àjẹkù ó jọ, ohunkóhun ṣe ṣòfò." 13 Bẹ́̀ ni wọ́n wọn jọ wọ́n fi àjẹkù ìṣù àkàrà barle márùn-ún náà kún agbọ̀n méjìlá, èyí àwọn ó jẹun jẹ .

14 6.14: Mt 21.11. Nítorí náà nígbà àwọn ọkùnrin náà iṣẹ́ àmì Jesu ṣe, wọ́n , "Lóòótọ́ èyí ni wòlíì náà ń bọ̀ ayé." 15 6.15: Jh 6.3; 18.36.Nígbà Jesu wòye wọ́n ń fẹ́ fi agbára òun láti lọ fi jẹ ọba, ó tún padà lọ sórí òkè, òun nìkan.

Jesu rin lórí omi

16 6.16-21: Mt 14.22-27; Mk 6.45-51. Nígbà alẹ́ lẹ́, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ lọ Òkun. 17 Wọ́n bọ́ sínú ọkọ̀ ojú omi, wọ́n rékọjá Òkun lọ Kapernaumu. Ilẹ̀ ti ṣú, Jesu ì ̀dọ̀ wọn. 18 Òkun ń ru nítorí ̀fúùfù líle ń fẹ́. 19 Nígbà wọ́n wa ọkọ̀ ojú omi ìwọ̀n ibùsọ̀ mẹ́̀́dọ́gbọ̀n tàbí ọgbọ̀n, wọ́n Jesu ń rìn lórí Òkun, ó súnmọ́ ọkọ̀ ojú omi náà; ̀wọ́n. 20 Ṣùgbọ́n ó fún wọn , "Èmi ni; bẹ̀." 21 Nítorí náà wọ́n fi ayọ̀ gbà á sínú ọkọ̀; lójúkan náà ọkọ̀ náà ilẹ̀ ibi wọ́n ń lọ.

22 ọjọ́ kejì nígbà àwọn ènìyàn ó dúró òdìkejì Òkun i , ọkọ̀ ojú omi mìíràn níbẹ̀, ṣe ̀kan náà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wọ̀, àti Jesu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wọ inú ọkọ̀ ojú omi náà, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ nìkan ni ó lọ. 23 Ṣùgbọ́n àwọn ọkọ̀ ojú omi mìíràn ti Tiberia , létí ibi wọn gbé jẹ àkàrà, lẹ́yìn ìgbà Olúwa ti dúpẹ́. 24 Nítorí náà nígbà àwọn ènìyàn i Jesu tàbí ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ níbẹ̀, àwọn pẹ̀wọ ọkọ̀ ojú omi lọ Kapernaumu, wọ́n ń Jesu.

Jesu oúnjẹ ìyè

25 Nígbà wọ́n i apá kejì Òkun, wọ́n fún un , "Rabbi, nígbà wo ni ìwọ síyìn-ín yìí?"

26 Jesu wọn lóhùn ó , "Lóòótọ́ lóòótọ́ ni mo fún yín. ̀yin ń mi, í ṣe nítorí ̀yin iṣẹ́ àmì, ṣùgbọ́n nítorí ̀yin jẹ àjẹyó ìṣù àkàrà. 27 6.27: Isa 55.2.ṣe ṣiṣẹ́ fún oúnjẹ ń ṣègbé, ṣùgbọ́n fún oúnjẹ ó títí di ayé àìnípẹ̀kun, èyí Ọmọ Ènìyàn yóò fi fún yín. Nítorí òun ni, àní Ọlọ́run Baba ti fi èdìdì í."

28 Nígbà náà ni wọ́n fún wọn , "Kín ni àwa ó ha ṣe, a ṣe iṣẹ́ Ọlọ́run?"

29 6.29: 1Tẹ 1.3; 1Jh 3.23. Jesu dáhùn, ó fún wọn , "Èyí ni iṣẹ́ Ọlọ́run , ̀yin gba ẹni ó rán an gbọ́."

30 6.30: Mt 12.38; Mk 8.11. Nígbà náà ni wọ́n fún wọn , "Iṣẹ́ àmì kín ìwọ ń ṣe, àwa , a gbà ́ gbọ́? Iṣẹ́ kín ìwọ ṣe? 31 6.31: El 16.4,15; Nu 11.8; Ne 9.15; Sm 78.24; 105.40.Àwọn baba wa jẹ manna aginjù; gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ , Ó fi oúnjẹ láti ̀run fún wọn jẹ.’ "

32 Nígbà náà ni Jesu fún wọn , "Lóòótọ́ lóòótọ́ ni mo fún yín, í ṣe Mose ni ó fi oúnjẹ fún yín láti ̀run , ṣùgbọ́n Baba mi ni ó fi oúnjẹ òtítọ́ náà fún yín láti ̀run . 33 Nítorí oúnjẹ Ọlọ́run ni èyí ó ti ̀run sọ̀kalẹ̀ , ó fi ìyè fún aráyé."

34 6.34: Jh 4.15; Mt 6.11. Nígbà náà ni wọ́n fún un , "Olúwa, máa fún wa oúnjẹ yìí títí láé."

35 6.35: Jh 6.48-50; 4.14. Jesu fún wọn , "Èmi ni oúnjẹ ìyè, ẹnikẹ́ni ó tọ̀ , ebi yóò pa á; ẹni ó gbà gbọ́, òǹgbẹ yóò gbẹ ́ mọ́ láé. 36 Ṣùgbọ́n mo fún yín , ̀yin ti mi, gbàgbọ́. 37 6.37: Jh 17.2.Gbogbo èyí Baba fi fún mi, yóò tọ̀ ; ẹni ó tọ̀ , èmi yóò á , ó . 38 6.38: Jh 4.34; 5.30.Nítorí èmi sọ̀kalẹ̀ láti ̀run , í ṣe láti máa ṣe ìfẹ́ ti èmi fúnra mi, ṣe ìfẹ́ ti ẹni ó rán mi. 39 6.39: Jh 17.12; 18.9.Èyí ni ìfẹ́ Baba ó rán mi ohun gbogbo o fi fún mi, èmi ṣe sọ ̀kan nínú wọn, ṣùgbọ́n èmi wọn dìde níkẹyìn ọjọ́. 40 6.40: Jh 5.29; 11.24; 6.54.Èyí ni ìfẹ́ ẹni ó rán mi, ẹnikẹ́ni ó wo ọmọ, ó gbà á gbọ́, ó ìyè àìnípẹ̀kun, Èmi ó i dìde níkẹyìn ọjọ́."

41 Nígbà náà ni àwọn Júù ń kùn i, nítorí ó , "Èmi ni oúnjẹ ó ti ̀run sọ̀kalẹ̀ ." 42 6.42: Lk 4.22; Jh 7.27.Wọ́n , "Jesu ha kọ́ èyí, ọmọ Josẹfu, baba àti ìyá ẹni àwa mọ̀? Báwo ni ó ṣe , Èmi ti ̀run sọ̀kalẹ̀ ?"

43 Nítorí náà Jesu dáhùn, ó fún wọn , "ṣe kùn láàrín yín! 44 6.44: Jr 31.3; Ho 11.4; Jh 12.32; 6.65.ẹnikẹ́ni ó sọ́dọ̀ mi, ṣe Baba ó rán mi á, Èmi ó i dìde níkẹyìn ọjọ́. 45 6.45: 1Tẹ 4.9; 1Jh 2.27; Isa 54.13.A à ti kọ ́ nínú ìwé àwọn wòlíì , A ó kọ́ gbogbo wọn láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ,nítorí náà ẹnikẹ́ni ó ti gbọ́, a ti ̀dọ̀ Baba kọ́, òun ni ó ń tọ̀ . 46 6.46: Jh 1.18.í ṣe ẹnìkan ti Baba ṣe ẹni ó ti ̀dọ̀ Ọlọ́run , òun ni ó ti Baba. 47 Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo fún yín, ẹni ó gbà gbọ́, ó ìyè àìnípẹ̀kun. 48 Èmi ni oúnjẹ ìyè. 49 Àwọn baba yín jẹ manna aginjù, wọ́n . 50 Èyí ni oúnjẹ ó ti ̀run sọ̀kalẹ̀ , ènìyàn máa jẹ nínú rẹ̀ ó . 51 Èmi ni oúnjẹ ìyè náà ó ti ̀run sọ̀kalẹ̀ , ẹnikẹ́ni jẹ nínú oúnjẹ yìí, yóò títí láéláé, oúnjẹ náà èmi ó fi fún ni fún ìyè aráyé ni ara mi."

52 6.52: Jh 3.4; 4.9. Nítorí náà ni àwọn Júù ṣe ń ara wọn jiyàn, , "Ọkùnrin yìí yóò ti ṣe fi ara rẹ̀ fún wa láti jẹ?"

53 Nígbà náà ni Jesu fún wọn , "Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo fún yín, ṣe ̀yin jẹ ara Ọmọ Ènìyàn, mu ̀jẹ̀ rẹ̀, ̀yin ìyè nínú yin. 54 Ẹnikẹ́ni ó jẹ ara mi, ó mu ̀jẹ̀ mi, ó ìyè nípẹ̀kun. Èmi o i dìde níkẹyìn ọjọ́. 55 Nítorí ara mi ni ohun jíjẹ nítòótọ́, àti ̀jẹ̀ mi ni ohun mímu nítòótọ́. 56 6.56: Jh 15.4; 1Jh 3.24; 4.15.Ẹni ó jẹ ara mi, ó mu ̀jẹ̀ mi, ó ń gbé inú mi, èmi ń gbé inú rẹ̀. 57 Gẹ́gẹ́ Baba alààyè ti rán mi, èmi nípa Baba gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni ẹni ó jẹ , òun pẹ̀yóò nípa mi. 58 6.58: Jh 6.41,51.Èyí ni oúnjẹ náà ó sọ̀kalẹ̀ láti ̀run , í ṣe àwọn baba yín ti jẹ manna, wọ́n , ẹni ó jẹ́ oúnjẹ yìí yóò láéláé." 59 6.59: Jh 6.25.Nǹkan wọ̀nyí ni ó sọ nínú Sinagọgu, ó ti ń kọ́ni Kapernaumu.

Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn yọ́ Jesu sílẹ̀

60 Nítorí náà nígbà ̀pọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ gbọ́ èyí, wọ́n , "̀rọ̀ ó le ni èyí; ta gbọ́ ?"

61 6.61: Mt 11.6. Nígbà Jesu mọ̀ nínú ara rẹ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń kùn ̀rọ̀ náà, ó fún wọn , "Èyí jẹ́ ìkọ̀sẹ̀ fún yín ? 62 6.62: Jh 3.13; 17.5.Ǹjẹ́, ̀yin i Ọmọ Ènìyàn ń gòkè lọ ibi ó gbé ti ń kọ́? 63 6.63: 2Kọ 3.6; Jh 6.68.̀ń sọ ni di ààyè; ara èrè kan; ̀rọ̀ wọ̀nyí mo sọ fún yín, ̀ni, ìyè ni pẹ̀. 64 6.64: Jh 2.25.Ṣùgbọ́n àwọn kan nínú yín gbàgbọ́." Nítorí Jesu mọ̀ láti ìbẹ̀rẹ̀ ẹni wọ́n jẹ́ gbàgbọ́, àti ẹni yóò fi òun hàn. 65 6.65: Jh 6.44; 3.27.Ó , "Nítorí náà ni mo ṣe fún yín , ẹni ó tọ̀ , ṣe a fi fún un láti ̀dọ̀ Baba mi ."

66 Nítorí èyí ̀pọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ padà sẹ́yìn, wọn a rìn mọ́.

67 Nítorí náà Jesu fún àwọn méjìlá , "̀yin pẹ̀ń fẹ́ lọ ?"

68 6.68-69: Mk 8.27-30. Nígbà náà ni Simoni Peteru a lóhùn , "Olúwa, ̀dọ̀ ta ni àwa ó lọ? Ìwọ ni ó ni ̀rọ̀ ìyè àìnípẹ̀kun. 69 Àwa ti gbàgbọ́, a mọ̀ ìwọ ni Kristi náà, Ọmọ Ọlọ́run alààyè."

70 6.70: Jh 15.16,19. Jesu wọn lóhùn , "̀yin méjìlá kọ́ ni mo yàn, ̀kan nínú yín ha ya èṣù?" 71 6.71: Jh 13.2,27; 17.12.(Ó ń sọ ti Judasi Iskariotu ọmọ Simoni ̀kan nínú àwọn méjìlá, nítorí òun ni ẹni yóò fi í hàn.)

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-