Publicidade

João 7

Jesu lọ àjọ ìpàgọ́

1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí Jesu ń rìn Galili, nítorí fẹ́ rìn Judea, nítorí àwọn Júù ń a láti pa. 2 Àjọ àwọn Júù í ṣe àjọ àgọ́ súnmọ́ etílé tan. 3 Nítorí náà, àwọn arákùnrin rẹ̀ fún un , "Lọ kúrò níhìn-ín yìí, o lọ Judea, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ pẹ̀fi iṣẹ́ rẹ hàn fún aráyé. 4 Nítorí ẹnikẹ́ni í ṣe ohunkóhun níkọ̀kọ̀, òun tìkára rẹ̀ ń fẹ́ a mọ òun gbangba. ìwọ ń ṣe nǹkan wọ̀nyí, fi ara rẹ hàn fún aráyé." 5 Nítorí àwọn arákùnrin rẹ̀ pàápàá tilẹ̀ gbà á gbọ́.

6 Nítorí náà ni Jesu fún wọn , "Àkókò gan an fún mi ì ; fún ̀yin, gbogbo àkókò ni ó dára fún yín. 7 Ayé kórìíra yín; ṣùgbọ́n èmi ni ó kórìíra, nítorí mo jẹ́rìí gbé é , iṣẹ́ rẹ̀ burú. 8 ̀yin gòkè lọ àjọ yìí, èmi yóò ì gòkè lọ àjọ yìí; nítorí àkókò mi ì ì ." 9 Nígbà ó ti sọ nǹkan wọ̀nyí fún wọn tan, ó dúró Galili síbẹ̀.

10 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn arákùnrin rẹ̀ gòkè lọ tan, nígbà náà ni òun gòkè lọ àjọ náà pẹ̀, í ṣe gbangba, ṣùgbọ́n ẹni níkọ̀kọ̀. 11 Nígbà náà ni àwọn Júù ń a kiri nígbà àjọ , "Níbo ni ó ?"

12 Ìkùnsínú púpọ̀ láàrín àwọn ìjọ ènìyàn nítorí rẹ̀, nítorí àwọn kan , "Ènìyàn rere í ṣe."

Àwọn mìíràn , "Bẹ́̀ kọ́, ṣùgbọ́n òun ń tan ènìyàn jẹ ni." 13 Ṣùgbọ́n ẹnìkan ó sọ̀rọ̀ rẹ̀ gbangba nítorí ìbẹ̀àwọn Júù.

Jesu kọ́ àwọn ènìyàn

14 Nígbà àjọ àárín; Jesu gòkè lọ tẹmpili ó ń kọ́ni. 15 Ẹnu ya àwọn Júù, wọ́n , "Ọkùnrin yìí ti ṣe mọ ìwé, nígbà kọ́ ̀kọ́?"

16 Jesu dáhùn, ó , "̀kọ́ mi í ṣe tèmi, ṣe ti ẹni ó rán mi. 17 ẹnikẹ́ni fẹ́ láti ṣe ìfẹ́ rẹ̀ yóò mọ̀ ti ̀kọ́ náà, ìbá ṣe ti Ọlọ́run, tàbí èmi sọ ti ara mi. 18 Ẹni ń sọ ti ara rẹ̀ ń ògo ara rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹni ń ògo ẹni ó rán an, òun ni olóòtítọ́, àìṣòdodo nínú rẹ̀. 19 Mose ha fi òfin fún yín, ẹnikẹ́ni nínú yín ó pa òfin náà mọ́? Èéṣe ̀yin fi ń ̀láti pa ?"

20 Ìjọ ènìyàn dáhùn, wọ́n , "Ìwọ ̀èṣù, ta ni ń ̀láti pa ́?"

21 Jesu dáhùn ó fún wọn , "Kìkì iṣẹ́ àmì kan ni mo ṣe, ẹnu ya gbogbo yín. 22 Síbẹ̀, nítorí Mose fi ìkọlà fún yín (tilẹ̀ kúkú láti ̀dọ̀ Mose ṣe láti ̀dọ̀ àwọn baba ńlá yín); nítorí náà ń kọ ènìyàn ilà ọjọ́ ìsinmi. 23 ènìyàn ń gba ìkọlà ọjọ́ ìsinmi, a ba à òfin Mose, ha ti ṣe ń bínú mi, nítorí mo ènìyàn kan láradá ọjọ́ ìsinmi? 24 ṣe ìdájọ́ nípa ti ara, ṣùgbọ́n máa ṣe ìdájọ́ òdodo."

Ṣé Jesu ni Kristi?

25 Nígbà náà ni àwọn kan nínú àwọn ará Jerusalẹmu , "Ẹni wọ́n ń ̀láti pa kọ́ yìí? 26 ó, ó ń sọ̀rọ̀ gbangba, wọn nǹkan kan i. Àwọn olórí ha mọ̀ nítòótọ́ , èyí ni Kristi náà? 27 Ṣùgbọ́n àwa mọ ibi ọkùnrin gbé ti , ṣùgbọ́n nígbà Kristi , ẹni yóò mọ ibi ó gbé ti ."

28 Nígbà náà ni Jesu kígbe tẹmpili ó ti ń kọ́ni, , "̀yin mọ̀ , mọ ibi mo ti , èmi fún ara mi, ṣùgbọ́n olóòtítọ́ ni ẹni ó rán mi, ẹni ̀yin mọ̀. 29 Ṣùgbọ́n èmi mọ̀ ́n, nítorí lọ́dọ̀ rẹ̀ ni mo ti , òun ni ó rán mi."

30 Nítorí náà wọ́n ń ̀à ti un, ṣùgbọ́n ẹnìkan ó gbé ọwọ́ e, nítorí wákàtí rẹ̀ ì . 31 ̀pọ̀ nínú ìjọ ènìyàn gbà á gbọ́, wọ́n , "Nígbà Kristi náà , yóò ha ṣe iṣẹ́ àmì wọ̀nyí, ọkùnrin yìí ti ṣe lọ?"

32 Àwọn Farisi gbọ́ , ìjọ ènìyàn ń sọ nǹkan wọ̀nyí lábẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀; àwọn Farisi àti àwọn olórí àlùfáà rán àwọn oníṣẹ́ lọ láti un.

33 Nítorí náà Jesu fún wọn , "Níwọ́n ìgbà díẹ̀ ni èmi yóò pẹ̀yín, èmi yóò lọ ̀dọ̀ ẹni ó rán mi. 34 ̀yin yóò mi, ̀yin yóò mi, àti ibi èmi , ̀yin yóò le ."

35 Nítorí náà ni àwọn Júù ń ara wọn sọ , "Níbo ni ọkùnrin yìí yóò gbé lọ àwa yóò fi i? Yóò ha lọ àárín àwọn Helleni wọ́n fọ́n káàkiri, ó máa kọ́ àwọn Helleni . 36 ̀rọ̀ kín ni èyí ó sọ yìí, ̀yin yóò mi, yóò mi, àti Ibi èmi ̀yin yóò le ?"

37 Lọ́jọ́ kẹ́yìn, í ṣe ọjọ́ ńlá àjọ, Jesu dúró, ó kígbe , "òǹgbẹ ń gbẹ ẹnikẹ́ni, ó tọ̀ , ó mu. 38 Ẹnikẹ́ni ó gbà gbọ́ gẹ́gẹ́ Ìwé Mímọ́ ti , láti inú rẹ̀ ni odò omi ìyè yóò ti máa sàn jáde ." 39 Ṣùgbọ́n ó sọ èyí ti ̀, àwọn ó gbà á gbọ́ ń bọ̀ gbà, nítorí a ì fi Èmí Mímọ́ fún ni; nítorí a ì ṣe Jesu lógo.

40 Nítorí náà, nígbà ̀pọ̀ nínú ìjọ ènìyàn gbọ́ ̀rọ̀ wọ̀nyí, wọ́n , "Lóòótọ́ èyí ni wòlíì náà."

41 Àwọn mìíràn , "Èyí ni Kristi náà."

Ṣùgbọ́n àwọn kan kínla, "Kristi yóò ha ti Galili ? 42 Ìwé mímọ́ ha , Kristi yóò ti inú irú-ọmọ Dafidi , àti Bẹtilẹhẹmu, ìlú Dafidi ti ?" 43 Bẹ́̀ ni ìyapa láàrín ìjọ ènìyàn nítorí rẹ̀. 44 Àwọn mìíràn nínú wọn fẹ́ láti un; ṣùgbọ́n ẹnìkan ó gbé ọwọ́ e.

Àìgbàgbọ́ àwọn adarí Júù

45 ìparí, àwọn ̀ṣọ́ tẹmpili padà tọ àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi lọ, wọ́n fún wọn , "Èéṣe ̀yin fi un ?"

46 Àwọn ̀ṣọ́ dáhùn , "ẹni ó ì sọ̀rọ̀ ọkùnrin yìí !"

47 Nítorí náà àwọn Farisi wọn lóhùn , "A ha tan ̀yin jẹ pẹ̀? 48 Ǹjẹ́ nínú àwọn ìjòyè, tàbí àwọn Farisi ti gbà á gbọ́ ? 49 Ṣùgbọ́n ìjọ ènìyàn yìí, ko mọ òfin di ẹni ìfibú."

50 Nikodemu ẹni ó tọ Jesu lóru , ó jẹ́ ̀kan nínú wọn sọ fún wọn , 51 "Òfin wa ha ń ṣe ìdájọ́ ènìyàn ó gbọ́ ti ẹnu rẹ̀ àti ó mọ ohun ó ṣe ?"

52 Wọ́n dáhùn wọ́n fún un , "Ìwọ pẹ̀láti Galili ? kiri, o nítorí wòlíì kan ó ti Galili dìde."

53 Wọ́n lọ olúkúlùkù ilé rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-