Publicidade

Lucas 1

1 ̀pọ̀ ènìyàn ni ó ti dáwọ́títo àwọn nǹkan wọ̀n-ọn-nì jọ lẹ́sẹẹsẹ, èyí ó ti múlẹ̀ ṣinṣin láàrín wa, 2 1.2: 1Jh 1.1; Ap 1.21; Hb 2.3.àní gẹ́gẹ́ àwọn ìránṣẹ́ ̀rọ̀ náà, ó ṣe ojú wọn láti ìbẹ̀rẹ̀ ti fi wa lọ́wọ́. 3 1.3: Ap 1.1.Nítorí náà, ó yẹ fún èmi pẹ̀, láti kọ̀lẹ́sẹẹsẹ mo ti wádìí ohun gbogbo fínní fínní láti ìpilẹ̀ṣẹ̀, Teofilu ọlọ́jùlọ, 4 1.4: Jh 20.31.ìwọ ó le mọ òtítọ́ ohun wọ̀n-ọn-nì, a ti kọ́ .

Àsọtẹ́lẹ̀ nípa ibí Johanu onítẹ̀bọmi

5 1.5: Mt 2.1; 1Ki 24.10; 2Ki 31.2. Nígbà ọjọ́ Herodu ọba Judea, àlùfáà kan , láti ìran Abijah, orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Sekariah: aya rẹ̀ ṣe ̀kan nínú àwọn ọmọbìnrin Aaroni, orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Elisabeti. 6 Àwọn méjèèjì ṣe olódodo níwájú Ọlọ́run, wọ́n ń rìn gbogbo òfin àti ìlànà Olúwa àìlẹ́gàn. 7 Ṣùgbọ́n wọn ọmọ, nítorí Elisabeti yàgàn; àwọn méjèèjì di arúgbó.

8 Ó ṣe, nígbà ó ń ṣe iṣẹ́ àlùfáà níwájú Ọlọ́run ni àkókò tirẹ̀. 9 1.9: Ek 30.7.ìṣe àwọn àlùfáà, ipa tirẹ̀ ni láti máa fi tùràrí jóná, nígbà ó wọ inú tẹmpili Olúwa lọ. 10 Gbogbo ìjọ àwọn ènìyàn ń gbàdúrà lóde àkókò sísun tùràrí.

11 1.11: Lk 2.9; Ap 5.19. Angẹli Olúwa kan fi ara hàn án, ó dúró apá ̀tún pẹpẹ tùràrí. 12 Nígbà Sekariah i, orí rẹ̀ , ̀á. 13 1.13: Lk 1.30,60.Ṣùgbọ́n angẹli náà fún un , "bẹ̀, Sekariah: nítorí àdúrà rẹ gbà; Elisabeti aya rẹ yóò ọmọkùnrin kan fún , ìwọ ó sọ orúkọ rẹ̀ Johanu. 14 Òun yóò jẹ́ ayọ̀ àti ìdùnnú fún , ènìyàn púpọ̀ yóò yọ̀ ìbí rẹ. 15 1.15: Nu 6.3; Lk 7.33.Nítorí òun ó pọ̀ níwájú Olúwa, yóò mu ọtí wáìnì, bẹ́̀ ni yóò mu ọtí líle; yóò kún fún ̀Mímọ́ àní láti inú ìyá rẹ̀ . 16 Òun ó ènìyàn púpọ̀ padà nínú àwọn ọmọ Israẹli Olúwa Ọlọ́run wọn. 17 1.17: Mt 11.14; 17.13; Ml 4.5.̀àti agbára Elijah ni Olúwa yóò fi ṣáájú rẹ̀ lọ, láti pa ọkàn àwọn baba ti àwọn ọmọ, àti ti àwọn aláìgbọ́ràn ọgbọ́n àwọn olóòtítọ́; ó le pèsè àwọn ènìyàn a múra sílẹ̀ de Olúwa."

18 Sekariah fún angẹli náà , "Àmì wo ni èmi ó fi mọ èyí? Èmi ti di àgbà, àti Elisabeti aya mi di arúgbó."

19 1.19: Da 8.16; 9.21; Mt 18.10. Angẹli náà dáhùn ó fún un , "Èmi ni Gabrieli, máa ń dúró níwájú Ọlọ́run; èmi ni a rán láti sọ fún , àti láti ìròyìn ayọ̀ wọ̀nyí fún . 20 kíyèsi i, ìwọ ó yadi, ìwọ yóò le fọhùn, títí ọjọ́ náà nǹkan wọ̀nyí yóò fi ṣẹ, nítorí ìwọ gba ̀rọ̀ mi gbọ́ yóò ṣẹ àkókò wọn."

21 Àwọn ènìyàn ń dúró de Sekariah, ẹnu wọ́n nítorí ó pẹ́ nínú tẹmpili. 22 Nígbà ó jáde , òun le wọn sọ̀rọ̀. Wọn kíyèsi ó ti ìran nínú tẹmpili, ó ń ṣe àpẹẹrẹ wọn, nítorí ó yadi.

23 Ó ṣe, nígbà ọjọ́ iṣẹ́ ìsìn rẹ̀ , ó lọ ilé rẹ̀. 24 Lẹ́yìn èyí ni Elisabeti aya rẹ̀ lóyún, ó fi ara rẹ̀ pamọ́ oṣù márùn-ún, 25 Ó , "Báyìí ni Olúwa ṣe fún mi ọjọ́ ó síjú , láti ̀gàn mi kúrò láàrín àwọn ènìyàn."

Ìsọtẹ́lẹ̀ ibi Jesu

26 oṣù kẹfà Ọlọ́run rán angẹli Gabrieli ìlú kan Galili, à ń Nasareti, 27 wúńdíá kan a ṣèlérí láti fẹ́ fún ọkùnrin kan, a ń Josẹfu, ti ìdílé Dafidi; orúkọ wúńdíá náà a máa jẹ́ Maria. 28 Angẹli náà tọ̀ ́ , ó , "Àlàáfíà fun , ìwọ ẹni a kọjú ṣe oore, Olúwa ń bẹ pẹ̀rẹ."

29 Ṣùgbọ́n ọkàn Maria lélẹ̀ nítorí ̀rọ̀ náà, ó nínú ara rẹ̀ , irú kíkí kín ni èyí. 30 1.30: Lk 1.13.Ṣùgbọ́n angẹli náà fún un , "bẹ̀, Maria, nítorí ìwọ ti ojúrere lọ́dọ̀ Ọlọ́run. 31 1.31: Lk 2.21; Mt 1.21.Ìwọ yóò lóyún nínú rẹ, ìwọ ó ọmọkùnrin kan, ìwọ ó pe orúkọ rẹ̀ Jesu. 32 Òun ó pọ̀, ọmọ ̀gá-ògo jùlọ ni a ó máa é, Olúwa Ọlọ́run yóò fi ìtẹ́ Dafidi baba rẹ̀ fún. 33 1.33: Mt 28.18; Da 2.44.Yóò jẹ ọba lórí ilé Jakọbu títí láé; ìjọba rẹ̀ yóò ìpẹ̀kun."

34 1.34: Lk 1.18. Nígbà náà ni Maria béèrè lọ́wọ́ angẹli náà , "Èyí yóò ha ti ṣe bẹ́̀, nígbà èmi ì mọ ọkùnrin."

35 1.35: Mt 1.20. Angẹli náà dáhùn ó fún un , "̀Mímọ́ yóò tọ̀ ́ , agbára ̀gá-ògo jùlọ yóò síji ́. Nítorí náà ohun mímọ́ a ó ti inú rẹ , Ọmọ Ọlọ́run ni a ó máa é. 36 kíyèsi i, Elisabeti ìbátan rẹ náà yóò ọmọkùnrin kan ògbólógbòó rẹ̀, èyí ni oṣù kẹfà fún ẹni à ń àgàn. 37 1.37: Gẹ 18.14.Nítorí ohun Ọlọ́run le ṣe."

38 Maria dáhùn , "ó ọmọ ̀dọ̀ Olúwa; ó fún mi gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ rẹ." Angẹli náà fi í sílẹ̀ lọ.

Maria bẹ Elisabeti

39 àkókò náà ni Maria dìde, ó lọ kánkán ilẹ̀ òkè, ìlú kan Judea; 40 Ó wọ ilé Sekariah lọ ó Elisabeti. 41 Ó ṣe, nígbà Elisabeti gbọ́ kíkí Maria, ọlẹ̀ sọ nínú rẹ̀; Elisabeti kún fún ̀Mímọ́, 42 1.42: Lk 11.27-28.Ó ohùn rara, ó , "Alábùkún fún ni ìwọ nínú àwọn obìnrin, alábùkún fún ni ọmọ ìwọ yóò . 43 Èéṣe èmi fi irú ojúrere yìí, ìyá Olúwa mi ìbá fi tọ̀ ? 44 ó, ohùn kíkí rẹ ti bọ́ mi etí, ọlẹ̀ sọ nínú mi fún ayọ̀. 45 Alábùkún fún ni ẹni ó gbàgbọ́, nítorí nǹkan wọ̀nyí a ti sọ fún un láti ̀dọ̀ Olúwa yóò ṣẹ."

Orin Maria

46 Maria dáhùn, ó :

"Ọkàn mi yin Olúwa lógo.

47 ̀mi yọ̀ Ọlọ́run Olùgbàlà mi.

48 Nítorí ó síjú wo ìwà ìrẹ̀lẹ̀

ọmọbìnrin ̀dọ̀ rẹ̀. ó,

láti ìsinsin yìí lọ gbogbo ìran ènìyàn ni yóò máa alábùkún fún.

49 Nítorí ẹni ó agbára ti ṣe ohun ó tóbi fún mi;

Mímọ́ ni orúkọ rẹ̀.

50 Àánú rẹ̀ ń bẹ fún àwọn ó bẹ̀rẹ̀,

láti ìrandíran.

51 Ó ti fi agbára hàn apá rẹ̀;

o ti àwọn onígbèéraga ìrònú ọkàn wọn.

52 Ó ti àwọn alágbára kúrò lórí ìtẹ́ wọn,

o gbé àwọn onírẹ̀lẹ̀ lékè.

53 Ó ti fi ohun ó dára kún àwọn ebi ń pa

ó rán àwọn ọlọ́rọ̀ padà òfo.

54 Ó ti ran Israẹli ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́,

ìrántí àánú rẹ̀;

55 1.55: Mt 7.20; Gẹ 17.7; 18.18; 22.17. Abrahamu àti àwọn ìran rẹ̀ láéláé, baba wa,

àti ó ti sọ fún àwọn baba wa."

56 Maria jókòó Elisabeti níwọ̀n oṣù mẹ́ta, ó padà lọ ilé rẹ̀.

Ìbí Johanu onítẹ̀bọmi

57 Nígbà ọjọ́ Elisabeti yóò ; ó ọmọkùnrin kan. 58 Àwọn aládùúgbò, àti àwọn ìbátan rẹ̀ gbọ́ Olúwa ti fi àánú ńlá hàn fún un, wọ́n a yọ̀.

59 1.59: Le 12.3; Gẹ 17.12. Ó ṣe, ọjọ́ kẹjọ wọ́n láti kọ ọmọ náà nílà; wọ́n fẹ́ sọ orúkọ rẹ̀ Sekariah, gẹ́gẹ́ orúkọ baba rẹ̀. 60 Ìyá rẹ̀ dáhùn, ó , "Bẹ́̀ kọ́! Johanu ni a ó é."

61 Wọ́n fún un , "̀kan nínú àwọn ará rẹ̀ à ń orúkọ yìí."

62 Wọ́n ṣe àpẹẹrẹ baba rẹ̀, ó ti ń fẹ́ a é. 63 Ó béèrè fún wàláà, ó kọ , "Johanu ni orúkọ rẹ̀." Ẹnu ya gbogbo wọn. 64 Ẹnu rẹ̀ ṣí lọ́gán, okùn ahọ́n rẹ̀ , ó sọ̀rọ̀, ó ń yin Ọlọ́run. 65 ̀ba gbogbo àwọn ń bẹ agbègbè wọn, a ròyìn gbogbo nǹkan wọ̀nyí gbogbo ilẹ̀ òkè Judea. 66 Ó jẹ́ ohun ìyanu fún gbogbo àwọn ó gbọ́ nípa rẹ̀, wọ́n ó sínú ọkàn wọn, wọ́n ń , "Irú-ọmọ kín ni èyí yóò jẹ́?" Nítorí ọwọ́ Olúwa pẹ̀rẹ̀.

Orin Sakariah

67 Sekariah baba rẹ̀ kún fún ̀Mímọ́, ó sọtẹ́lẹ̀, ó :

68 "Olùbùkún ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli;

nítorí ó ti bojú , ó ti àwọn ènìyàn rẹ̀ nídè,

69 Ó ti gbé ìwo ìgbàlà sókè fún wa

ilé Dafidi ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀;

70 (ó ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu àwọn wòlíì rẹ̀ mímọ́ tipẹ́tipẹ́),

71 , a ó gbà lọ́wọ́

àwọn ̀wa àti lọ́wọ́ àwọn ó kórìíra .

72 Láti ṣe àánú ó ṣèlérí fún àwọn baba wa,

àti láti rántí májẹ̀rẹ̀ mímọ́,

73 ìbúra ó ti fún Abrahamu baba wa,

74 láti gbà lọ́wọ́ àwọn ̀wa,

àwa ó máa sìn láìfòyà,

75 ni ìwà mímọ́ àti òdodo níwájú rẹ̀, ọjọ́ ayé wa gbogbo.

76 1.76: Lk 7.26; Ml 4.5. "Àti ìwọ, ọmọ mi, wòlíì ̀gá-ògo jùlọ ni a ó máa ́:

nítorí ìwọ ni yóò ṣáájú Olúwa láti tún ̀rẹ̀ ṣe;

77 1.77: Mk 1.4. láti fi ìmọ̀ ìgbàlà fún àwọn ènìyàn rẹ̀

fún ìmúkúrò ̀ṣẹ̀ wọn,

78 1.78: Ml 4.2; Ef 5.14. nítorí ìyọ́Ọlọ́run ;

nípa èyí ìlà-oòrùn láti òkè bojú ,

79 1.79: Isa 9.2; Mt 4.16. Láti fi ìmọ́lẹ̀ fún àwọn ó jókòó

òkùnkùn àti òjìji ikú,

àti láti fi ẹsẹ̀ wa ̀àlàáfíà."

80 1.80: Lk 2.40; 2.52. Ọmọ náà dàgbà, ó le ọkàn, ó ń gbé ijù títí ó fi di ọjọ́ ìfihàn rẹ̀ fún Israẹli.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-