Publicidade

Lucas 1

1 ̀pọ̀ ènìyàn ni ó ti dáwọ́títo àwọn nǹkan wọ̀n-ọn-nì jọ lẹ́sẹẹsẹ, èyí ó ti múlẹ̀ ṣinṣin láàrín wa, 2 àní gẹ́gẹ́ àwọn ìránṣẹ́ ̀rọ̀ náà, ó ṣe ojú wọn láti ìbẹ̀rẹ̀ ti fi wa lọ́wọ́. 3 Nítorí náà, ó yẹ fún èmi pẹ̀, láti kọ̀lẹ́sẹẹsẹ mo ti wádìí ohun gbogbo fínní fínní láti ìpilẹ̀ṣẹ̀, Teofilu ọlọ́jùlọ, 4 ìwọ ó le mọ òtítọ́ ohun wọ̀n-ọn-nì, a ti kọ́ .

Àsọtẹ́lẹ̀ nípa ibí Johanu onítẹ̀bọmi

5 Nígbà ọjọ́ Herodu ọba Judea, àlùfáà kan , láti ìran Abijah, orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Sekariah: aya rẹ̀ ṣe ̀kan nínú àwọn ọmọbìnrin Aaroni, orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Elisabeti. 6 Àwọn méjèèjì ṣe olódodo níwájú Ọlọ́run, wọ́n ń rìn gbogbo òfin àti ìlànà Olúwa àìlẹ́gàn. 7 Ṣùgbọ́n wọn ọmọ, nítorí Elisabeti yàgàn; àwọn méjèèjì di arúgbó.

8 Ó ṣe, nígbà ó ń ṣe iṣẹ́ àlùfáà níwájú Ọlọ́run ni àkókò tirẹ̀. 9 ìṣe àwọn àlùfáà, ipa tirẹ̀ ni láti máa fi tùràrí jóná, nígbà ó wọ inú tẹmpili Olúwa lọ. 10 Gbogbo ìjọ àwọn ènìyàn ń gbàdúrà lóde àkókò sísun tùràrí.

11 Angẹli Olúwa kan fi ara hàn án, ó dúró apá ̀tún pẹpẹ tùràrí. 12 Nígbà Sekariah i, orí rẹ̀ , ̀á. 13 Ṣùgbọ́n angẹli náà fún un , "bẹ̀, Sekariah: nítorí àdúrà rẹ gbà; Elisabeti aya rẹ yóò ọmọkùnrin kan fún , ìwọ ó sọ orúkọ rẹ̀ Johanu. 14 Òun yóò jẹ́ ayọ̀ àti ìdùnnú fún , ènìyàn púpọ̀ yóò yọ̀ ìbí rẹ. 15 Nítorí òun ó pọ̀ níwájú Olúwa, yóò mu ọtí wáìnì, bẹ́̀ ni yóò mu ọtí líle; yóò kún fún ̀Mímọ́ àní láti inú ìyá rẹ̀ . 16 Òun ó ènìyàn púpọ̀ padà nínú àwọn ọmọ Israẹli Olúwa Ọlọ́run wọn. 17 ̀àti agbára Elijah ni Olúwa yóò fi ṣáájú rẹ̀ lọ, láti pa ọkàn àwọn baba ti àwọn ọmọ, àti ti àwọn aláìgbọ́ràn ọgbọ́n àwọn olóòtítọ́; ó le pèsè àwọn ènìyàn a múra sílẹ̀ de Olúwa."

18 Sekariah fún angẹli náà , "Àmì wo ni èmi ó fi mọ èyí? Èmi ti di àgbà, àti Elisabeti aya mi di arúgbó."

19 Angẹli náà dáhùn ó fún un , "Èmi ni Gabrieli, máa ń dúró níwájú Ọlọ́run; èmi ni a rán láti sọ fún , àti láti ìròyìn ayọ̀ wọ̀nyí fún . 20 kíyèsi i, ìwọ ó yadi, ìwọ yóò le fọhùn, títí ọjọ́ náà nǹkan wọ̀nyí yóò fi ṣẹ, nítorí ìwọ gba ̀rọ̀ mi gbọ́ yóò ṣẹ àkókò wọn."

21 Àwọn ènìyàn ń dúró de Sekariah, ẹnu wọ́n nítorí ó pẹ́ nínú tẹmpili. 22 Nígbà ó jáde , òun le wọn sọ̀rọ̀. Wọn kíyèsi ó ti ìran nínú tẹmpili, ó ń ṣe àpẹẹrẹ wọn, nítorí ó yadi.

23 Ó ṣe, nígbà ọjọ́ iṣẹ́ ìsìn rẹ̀ , ó lọ ilé rẹ̀. 24 Lẹ́yìn èyí ni Elisabeti aya rẹ̀ lóyún, ó fi ara rẹ̀ pamọ́ oṣù márùn-ún, 25 Ó , "Báyìí ni Olúwa ṣe fún mi ọjọ́ ó síjú , láti ̀gàn mi kúrò láàrín àwọn ènìyàn."

Ìsọtẹ́lẹ̀ ibi Jesu

26 oṣù kẹfà Ọlọ́run rán angẹli Gabrieli ìlú kan Galili, à ń Nasareti, 27 wúńdíá kan a ṣèlérí láti fẹ́ fún ọkùnrin kan, a ń Josẹfu, ti ìdílé Dafidi; orúkọ wúńdíá náà a máa jẹ́ Maria. 28 Angẹli náà tọ̀ ́ , ó , "Àlàáfíà fun , ìwọ ẹni a kọjú ṣe oore, Olúwa ń bẹ pẹ̀rẹ."

29 Ṣùgbọ́n ọkàn Maria lélẹ̀ nítorí ̀rọ̀ náà, ó nínú ara rẹ̀ , irú kíkí kín ni èyí. 30 Ṣùgbọ́n angẹli náà fún un , "bẹ̀, Maria, nítorí ìwọ ti ojúrere lọ́dọ̀ Ọlọ́run. 31 Ìwọ yóò lóyún nínú rẹ, ìwọ ó ọmọkùnrin kan, ìwọ ó pe orúkọ rẹ̀ Jesu. 32 Òun ó pọ̀, ọmọ ̀gá-ògo jùlọ ni a ó máa é, Olúwa Ọlọ́run yóò fi ìtẹ́ Dafidi baba rẹ̀ fún. 33 Yóò jẹ ọba lórí ilé Jakọbu títí láé; ìjọba rẹ̀ yóò ìpẹ̀kun."

34 Nígbà náà ni Maria béèrè lọ́wọ́ angẹli náà , "Èyí yóò ha ti ṣe bẹ́̀, nígbà èmi ì mọ ọkùnrin."

35 Angẹli náà dáhùn ó fún un , "̀Mímọ́ yóò tọ̀ ́ , agbára ̀gá-ògo jùlọ yóò síji ́. Nítorí náà ohun mímọ́ a ó ti inú rẹ , Ọmọ Ọlọ́run ni a ó máa é. 36 kíyèsi i, Elisabeti ìbátan rẹ náà yóò ọmọkùnrin kan ògbólógbòó rẹ̀, èyí ni oṣù kẹfà fún ẹni à ń àgàn. 37 Nítorí ohun Ọlọ́run le ṣe."

38 Maria dáhùn , "ó ọmọ ̀dọ̀ Olúwa; ó fún mi gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ rẹ." Angẹli náà fi í sílẹ̀ lọ.

Maria bẹ Elisabeti

39 àkókò náà ni Maria dìde, ó lọ kánkán ilẹ̀ òkè, ìlú kan Judea; 40 Ó wọ ilé Sekariah lọ ó Elisabeti. 41 Ó ṣe, nígbà Elisabeti gbọ́ kíkí Maria, ọlẹ̀ sọ nínú rẹ̀; Elisabeti kún fún ̀Mímọ́, 42 Ó ohùn rara, ó , "Alábùkún fún ni ìwọ nínú àwọn obìnrin, alábùkún fún ni ọmọ ìwọ yóò . 43 Èéṣe èmi fi irú ojúrere yìí, ìyá Olúwa mi ìbá fi tọ̀ ? 44 ó, ohùn kíkí rẹ ti bọ́ mi etí, ọlẹ̀ sọ nínú mi fún ayọ̀. 45 Alábùkún fún ni ẹni ó gbàgbọ́, nítorí nǹkan wọ̀nyí a ti sọ fún un láti ̀dọ̀ Olúwa yóò ṣẹ."

Orin Maria

46 Maria dáhùn, ó :

"Ọkàn mi yin Olúwa lógo.

47 ̀mi yọ̀ Ọlọ́run Olùgbàlà mi.

48 Nítorí ó síjú wo ìwà ìrẹ̀lẹ̀

ọmọbìnrin ̀dọ̀ rẹ̀. ó,

láti ìsinsin yìí lọ gbogbo ìran ènìyàn ni yóò máa alábùkún fún.

49 Nítorí ẹni ó agbára ti ṣe ohun ó tóbi fún mi;

Mímọ́ ni orúkọ rẹ̀.

50 Àánú rẹ̀ ń bẹ fún àwọn ó bẹ̀rẹ̀,

láti ìrandíran.

51 Ó ti fi agbára hàn apá rẹ̀;

o ti àwọn onígbèéraga ìrònú ọkàn wọn.

52 Ó ti àwọn alágbára kúrò lórí ìtẹ́ wọn,

o gbé àwọn onírẹ̀lẹ̀ lékè.

53 Ó ti fi ohun ó dára kún àwọn ebi ń pa

ó rán àwọn ọlọ́rọ̀ padà òfo.

54 Ó ti ran Israẹli ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́,

ìrántí àánú rẹ̀;

55 Abrahamu àti àwọn ìran rẹ̀ láéláé, baba wa,

àti ó ti sọ fún àwọn baba wa."

56 Maria jókòó Elisabeti níwọ̀n oṣù mẹ́ta, ó padà lọ ilé rẹ̀.

Ìbí Johanu onítẹ̀bọmi

57 Nígbà ọjọ́ Elisabeti yóò ; ó ọmọkùnrin kan. 58 Àwọn aládùúgbò, àti àwọn ìbátan rẹ̀ gbọ́ Olúwa ti fi àánú ńlá hàn fún un, wọ́n a yọ̀.

59 Ó ṣe, ọjọ́ kẹjọ wọ́n láti kọ ọmọ náà nílà; wọ́n fẹ́ sọ orúkọ rẹ̀ Sekariah, gẹ́gẹ́ orúkọ baba rẹ̀. 60 Ìyá rẹ̀ dáhùn, ó , "Bẹ́̀ kọ́! Johanu ni a ó é."

61 Wọ́n fún un , "̀kan nínú àwọn ará rẹ̀ à ń orúkọ yìí."

62 Wọ́n ṣe àpẹẹrẹ baba rẹ̀, ó ti ń fẹ́ a é. 63 Ó béèrè fún wàláà, ó kọ , "Johanu ni orúkọ rẹ̀." Ẹnu ya gbogbo wọn. 64 Ẹnu rẹ̀ ṣí lọ́gán, okùn ahọ́n rẹ̀ , ó sọ̀rọ̀, ó ń yin Ọlọ́run. 65 ̀ba gbogbo àwọn ń bẹ agbègbè wọn, a ròyìn gbogbo nǹkan wọ̀nyí gbogbo ilẹ̀ òkè Judea. 66 Ó jẹ́ ohun ìyanu fún gbogbo àwọn ó gbọ́ nípa rẹ̀, wọ́n ó sínú ọkàn wọn, wọ́n ń , "Irú-ọmọ kín ni èyí yóò jẹ́?" Nítorí ọwọ́ Olúwa pẹ̀rẹ̀.

Orin Sakariah

67 Sekariah baba rẹ̀ kún fún ̀Mímọ́, ó sọtẹ́lẹ̀, ó :

68 "Olùbùkún ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli;

nítorí ó ti bojú , ó ti àwọn ènìyàn rẹ̀ nídè,

69 Ó ti gbé ìwo ìgbàlà sókè fún wa

ilé Dafidi ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀;

70 (ó ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu àwọn wòlíì rẹ̀ mímọ́ tipẹ́tipẹ́),

71 , a ó gbà lọ́wọ́

àwọn ̀wa àti lọ́wọ́ àwọn ó kórìíra .

72 Láti ṣe àánú ó ṣèlérí fún àwọn baba wa,

àti láti rántí májẹ̀rẹ̀ mímọ́,

73 ìbúra ó ti fún Abrahamu baba wa,

74 láti gbà lọ́wọ́ àwọn ̀wa,

àwa ó máa sìn láìfòyà,

75 ni ìwà mímọ́ àti òdodo níwájú rẹ̀, ọjọ́ ayé wa gbogbo.

76 "Àti ìwọ, ọmọ mi, wòlíì ̀gá-ògo jùlọ ni a ó máa ́:

nítorí ìwọ ni yóò ṣáájú Olúwa láti tún ̀rẹ̀ ṣe;

77 láti fi ìmọ̀ ìgbàlà fún àwọn ènìyàn rẹ̀

fún ìmúkúrò ̀ṣẹ̀ wọn,

78 nítorí ìyọ́Ọlọ́run ;

nípa èyí ìlà-oòrùn láti òkè bojú ,

79 Láti fi ìmọ́lẹ̀ fún àwọn ó jókòó

òkùnkùn àti òjìji ikú,

àti láti fi ẹsẹ̀ wa ̀àlàáfíà."

80 Ọmọ náà dàgbà, ó le ọkàn, ó ń gbé ijù títí ó fi di ọjọ́ ìfihàn rẹ̀ fún Israẹli.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-