Publicidade

Lucas 10

Òwe aláàánú ará Samaria

25 10.25-28: Mt 22.34-39; Mk 12.28-31. 10.25: Mk 10.17; Mt 19.16; Lk 18.18. kíyèsi i amòfin kan dìde, ó ń dán an , ó , "Olùkọ́, kín ni èmi ó ṣe èmi jogún ìyè àìnípẹ̀kun?"

26 Ó bi í , "ni a kọ sínú ìwé òfin? Báwo ni ìwọ ti á?"

27 10.27: De 6.5; Le 19.18; Ro 13.9; Ga 5.14; Jk 2.8. Ó dáhùn , " ìwọ fi gbogbo àyà rẹ, àti gbogbo ọkàn rẹ, àti gbogbo agbára rẹ, àti gbogbo inú rẹ fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ; àti, Ẹnìkejì rẹ ara rẹ.’ "

28 10.28: Lk 20.39; Le 18.25. Ó fún un , "Ìwọ́ dáhùn rere. Ṣe èyí, ìwọ ó ."

29 Ṣùgbọ́n ó ń fẹ́ láti da ara rẹ̀ láre, ó fún Jesu , "Ta ha ni ẹnìkejì mi?"

30 Jesu dáhùn ó , "Ọkùnrin kan ń ti Jerusalẹmu sọ̀kalẹ̀ lọ Jeriko, ó bọ́ ọwọ́ àwọn ọlọ́ṣà; wọ́n gbà á aṣọ, wọ́n a lọ́gbẹ́, wọ́n fi sílẹ̀ lọ àìpatán. 31 kòńgẹ́ àkókò yìí ni àlùfáà kan ń sọ̀kalẹ̀ lọ lọ́náà. Nígbà ó i ó kọjá lọ níhà kejì. 32 Bẹ́̀ náà ni ọmọ Lefi kan pẹ̀, nígbà ó ibẹ̀, ó i, ó kọjá lọ níhà kejì. 33 10.33: Lk 9.51-56; 17.11-19; Jh 4.4-42.Ṣùgbọ́n ará Samaria kan, ó ti ń re àjò, ó ibi ó gbé ; nígbà ó i, àánú ṣe é. 34 Ó tọ̀ ́ lọ, ó di ọgbẹ́ rẹ̀, ó da òróró àti ọtí wáìnì i, ó gbé e orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ti òun tìkára rẹ̀, ó un ilé èrò, a ń ṣe ìtọ́rẹ̀. 35 Nígbà ó lọ ọjọ́ kejì, ó fi owó idẹ méjì fún olórí ilé èrò ó fún un , Máa tọ́rẹ̀; ohunkóhun ìwọ kún un, nígbà mo padà , èmi ó san án fún .

36 "Nínú àwọn mẹ́tẹ̀̀ta wọ̀nyí, ta ni ìwọ ó jẹ́ ẹnìkejì ẹni ó bọ́ ọwọ́ àwọn ọlọ́ṣà?"

37 Ó dáhùn , "Ẹni ó ṣàánú fún un ni."

Jesu fún un , "Lọ, o ṣe bẹ́̀ gẹ́gẹ́!"

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-