Publicidade

Lucas 15

Òwe àgùntàn sọnù

1 Gbogbo àwọn agbowó òde àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ súnmọ́ ọn láti gbọ́ ̀rọ̀ rẹ̀. 2 Àti àwọn Farisi àti àwọn akọ̀ń kùn , "Ọkùnrin yìí ń gba ẹlẹ́ṣẹ̀, ó ń wọn jẹun."

3 Ó pa òwe yìí fún wọn, , 4 "Ọkùnrin wo ni nínú yín, ó ọgọ́rùn-ún àgùntàn, ó sọ ̀kan nínú wọn, yóò fi mọ́kàndínlọ́gọ́rùn-ún yokù sílẹ̀ ni ijù yóò tọ ipasẹ̀ èyí ó lọ, títí yóò fi i? 5 Nígbà ó i tán, yóò gbé e èjìká rẹ̀ pẹ̀ayọ̀. 6 Nígbà ó ilé yóò pe àwọn ̀rẹ́ àti aládùúgbò rẹ̀ jọ, yóò fún wọn , yọ̀; nítorí mo ti àgùntàn mi ó . 7 Mo fún yín, gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni ayọ̀ yóò ̀run lórí ẹlẹ́ṣẹ̀ kan ó ronúpìwàdà, ju lórí olóòtítọ́ mọ́kàndínlọ́gọ́rùn-ún lọ, nílò ìrònúpìwàdà.

Òwe owó sọnù

8 "Tàbí obìnrin wo ni ó owó fàdákà mẹ́wàá ó sọ ̀kan , yóò tan fìtílà, ó fi gbá ilé, ó a gidigidi títí yóò fi i? 9 Nígbà ó i, ó pe àwọn ̀rẹ́ àti àwọn aládùúgbò rẹ̀ jọ, ó , mi yọ̀; nítorí mo owó fàdákà mo ti sọnù. 10 Mo fún yín, gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni ayọ̀ ń bẹ níwájú àwọn angẹli Ọlọ́run lórí ẹlẹ́ṣẹ̀ kan ó ronúpìwàdà."

Òwe ọmọ sọnù

11 Ó ọkùnrin kan ọmọ méjì: 12 "Èyí àbúrò nínú wọn fún baba rẹ̀ , Baba, fún mi ìní ó kàn .Ó pín ohun ìní rẹ̀ fún wọn.

13 "ọjọ́ mélòó kan lẹ́yìn náà, èyí àbúrò ohun gbogbo ó jọ, ó ̀àjò rẹ̀ pọ̀n lọ ilẹ̀ òkèrè, níbẹ̀ ni ó gbé fi ìwà wọ̀bìà ohun ìní rẹ̀ ìnákúnàá. 14 Nígbà ó ba gbogbo rẹ̀ jẹ́ tan, ìyàn ńlá ilẹ̀ náà; ó bẹ̀rẹ̀ di aláìní. 15 Ó fi ara rẹ sọfà fun ̀kan lára àwọn ọmọ ìlú náà; òun rán an lọ oko rẹ̀ láti tọ́ẹlẹ́dẹ̀. 16 Ayọ̀ ni ìbá fi jẹ oúnjẹ àwọn ẹlẹ́dẹ̀ ń jẹ àjẹyó, ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni fi fún un.

17 "Ṣùgbọ́n nígbà ojú rẹ̀ wálẹ̀, ó Mélòó mélòó àwọn alágbàṣe baba ni ó oúnjẹ àjẹyó, àti àjẹtì, èmi ń fún ebi níhìn-ín. 18 Èmi ó dìde, èmi ó tọ baba mi lọ, èmi ó fún un , Baba, èmí ti dẹ́ṣẹ̀ ̀run, àti níwájú rẹ, 19 èmi yẹ, ẹni à ọmọ rẹ mọ́; fi ṣe ̀kan nínú àwọn alágbàṣe rẹ. 20 Ó dìde, ó tọ baba rẹ̀ lọ.

"Ṣùgbọ́n nígbà ó òkèrè, baba rẹ̀ i, àánú ṣe é, ó súré, ó rọ̀ mọ́ ọn ọrùn, ó fi ẹnu ó ẹnu.

21 "Ọmọ náà fún un , Baba, èmi ti dẹ́ṣẹ̀ ̀run, àti níwájú rẹ, èmi yẹ ẹni à ọmọ rẹ mọ́!

22 "Ṣùgbọ́n baba náà fún àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ , ààyò aṣọ kánkán, fi wọ̀ ́; fi òrùka bọ̀ ́ lọ́wọ́, àti bàtà ẹsẹ̀ rẹ̀: 23 ẹgbọrọ màlúù àbọ́pa , pa á, a máa ṣe àríyá. 24 Nítorí ọmọ mi yìí ti , ó tún , ó ti , a i. Wọ́n bẹ̀rẹ̀ í ṣe àríyá.

25 "Ṣùgbọ́n ọmọ rẹ̀ èyí ̀gbọ́n ti oko: ó ti ń bọ̀, ó súnmọ́ etí ilé, ó gbọ́ orin àti ijó. 26 Ó pe ̀kan nínú àwọn ọmọ ̀dọ̀ wọn, ó béèrè, kín ni a mọ nǹkan wọ̀nyí ? 27 Ó fún un , Arákùnrin rẹ , baba rẹ pa ẹgbọrọ màlúù àbọ́pa, nítorí ó i padà àlàáfíà àti ìlera.

28 "Ó bínú, ó kọ̀ láti wọlé; baba rẹ̀ jáde, ó í ṣìpẹ̀ fún un. 29 Ó dáhùn ó fún baba rẹ̀ , ó, láti ọdún mélòó wọ̀nyí ni èmi ti ń sìn ́, èmi òfin rẹ , ìwọ ì fi ọmọ ewúrẹ́ kan fún mi, láti fi àwọn ̀rẹ́ mi ṣe àríyá. 30 Ṣùgbọ́n nígbà ọmọ rẹ yìí , ẹni ó fi panṣágà fi ọrọ̀ rẹ̀ ṣòfò, ìwọ ti pa ẹgbọrọ màlúù àbọ́pa fún un.

31 "Ó fún un , Ọmọ, nígbà gbogbo ni ìwọ ń bẹ lọ́dọ̀ mi, ohun gbogbo mo , tìrẹ ni. 32 Ó yẹ a ṣe àríyá a yọ̀: nítorí arákùnrin rẹ yìí ti , ó tún ; ó ti , a i.’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-